Take a fresh look at your lifestyle.
Browsing Category

KÓKÓ INÚ ÌRÒYÌN

This is a category for featured story

Ààrẹ Tinubu Kí Alága NRS Zacch Adedeji Ẹní Ọmọ Ọdún mẹ́tàdínlàádọ́ta ‎

‎ Ààrẹ Bola Ahmed Tinubu ti kí Alága fún Iṣẹ́ Owó-orí Nàìjíríà (NRS), Dókítà Zacch Adedeji, ní ayẹyẹ Ọjọ́ìbí rẹ̀, O gbóríyìn ìtọ́sọ́nà rẹ̀ lórí ìyípadà ilé-iṣẹ́ owó-orí orílẹ̀-èdè náà. ‎ ‎ Nínú ìròyìn kán tí Agbẹnusọ Ààrẹ fi síta,…

Mínísítà Kẹ́dun Pẹ̀lú Àwọn Aráàlú Tó Pàdánù Àwọn Ènìyàn Nínú Ìkọlù Ìpínlẹ̀ Niger

Mínísítà fún Ìpínlẹ̀ fún Ise-ọgbin àti Ààbò Oúnjẹ tí Nàìjíríà, Aliyu Sabi Abdullahi, (Baraden Borgu), tí kẹ́dun pẹ̀lú àgbègbè Kasuwan Daji ní Ìjọba ìbílẹ̀ Borgu ní Ìpínlẹ̀ Niger lórí ikọlù tí àwọn oníjàgídíjàgan ṣé si agbègbè náà. ‎ ‎…

Igbákejì Ààrẹ Ilé Ìgbìmọ̀ Aṣòfin Pé Fún Ìṣọ́kan Àti Àjọṣepọ̀ Láàrín Àwọn Aláṣẹ Àti Aṣòfin  ‎

‎Igbákejì Ààrẹ Ilé Ìgbìmọ̀ Aṣòfin Nàìjíríà, Sẹ́nétọ̀ Barau Jibrin, ti pe fún ìfọwọ́sowọ́pọ̀ tó lágbára àti ọ̀wọ̀ láàrin àwọn Aláṣẹ àti Ilé Ìgbìmọ̀ Aṣòfin, gẹ́gẹ́ bí ọ̀nà pàtàkì láti mú kí ìjọba tiwantiwa ṣọ̀kan ní Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà. ‎…

COAS Ṣé Ìfọwọ́sowọ́pọ̀ Pẹ̀lú Àwọn Aṣíwájú Ní Ìpínlẹ̀ Niger Láti Dẹ́kun Ìpániláyà

Olórí Ẹgbẹ́ Àwọn Ọmọ-ogun ti mú ìsapá wọn pọ̀ sí i láti mú kí Ìpínlẹ̀ Niger dúró ṣinṣin nípa ṣíṣe ìfọwọ́sowọ́pọ̀ pẹ̀lú àwọn Ọba àti àwọn olórí ìbílẹ̀ nínú àtúnyẹ̀wò gbígbòòrò kán lórí ìfiránṣẹ́ àwọn ológun, ìmúlò ìmọ̀ ẹ̀rọ, àti ìmúrasílẹ̀…

Olórí Ẹgbẹ́ Ọmọ-ogun Tún Jẹ́rìí sí Ààbò Àwọn Ọmọ-ogun

Olórí Ẹgbẹ́ Ọmọ-ogun, Lt. Gen. Waidi Shaibu, ti tún ṣé ìdánilójú pé ẹgbẹ́ ọmọ-ogun Nàìjíríà yóò máa ṣètìlẹ́yìn fún àwọn olórí àti àwọn ọmọ-ogun pẹ̀lú àwọn ètò ìlera tó yẹ, àwọn ohun èlò ìṣiṣẹ́ àti àtìlẹ́yìn àwọn olórí tó yẹ láti jẹ́ kí wọn…

Ìkọlù Àwọn Agbébọn Sí Ọfiisi Ọgbà Ìtọ́jú Ẹranko Àtijọ́: Makinde Ṣèlérí Òpin Sí Irú Ìkọlù Bẹẹ

Látàrí ìṣẹ̀lẹ̀ ìkọlù àwọn agbébọn sí àwọn òṣìṣẹ́ ọgbà ìtọ́jú ẹranko àtijọ ni Gómìnà Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ ti rawọ́ ẹ̀bẹ̀ sí àwọn ènìyàn agbègbè náà láti ṣe sùúrù. Ìṣẹ̀lẹ̀ ìkọlù àwọn agbébọn eléyìí ti Alukoro ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́, DSP…
button