Browsing Category
KÓKÓ INÚ ÌRÒYÌN
This is a category for featured story
Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Gba Owó Ìbẹ̀rẹ̀ Àádọta Mílíọ̀nù Dọ́là$ Nípasẹ̀ Ìbáṣepọ̀ NSIA–JICA
Aláṣẹ Ìdókòwò Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà (NSIA) àti Ilé Iṣẹ́ Ìfọwọ́sowọ́pọ̀ Àgbáyé ti Orílẹ̀-èdè Japan (JICA) ti parí àdéhùn láti ṣe ìfilọ́lẹ̀ Owó Ìmúdàgba Àádọta mílíọ̀nù Dọ́là láti mú kí ètò ìṣẹ̀dá tuntun ní Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà lágbára síi.…
Aṣojú Ìṣúra Orílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà Ṣè Àbẹ̀wò sí Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà
Olùrànlọ́wọ́ Akọ̀wé fún Ìṣúra ni Orílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà, Jonathan Burke yóò ṣè àbẹ̀wò sí Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà láti ọjọ́ kẹtàlélógún sí ọjọ́ kẹrìnlélógún oṣù kejì, láti mú kí àjọṣepọ̀ pẹ̀lú Ìjọba Nàìjíríà lágbára síi lórí gbígbógun ti owó ìnáwó…
Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà fún Àwọn olùfowópamọ́ Kẹ́rẹ́je Ni Ààbò òfin.
Mínísítà fún Ìdàgbàsókè Àwọn Ohun Alumọ́ọ́nì Rírọrùn ní Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, Dele Alake, ti fi dá àwọn olùfowópamọ́ sí orílẹ̀-èdè òkèèrè ní ẹ̀ka iwakusa orílẹ̀-èdè náà lójú nípa ààbò òfin tó lágbára lábẹ́ àdéhùn Cape Town lórí Àwọn Ohun…
Ẹgbẹ́ APC Ìpínlẹ̀ Kwara Fọwọ́sí Àwọn Olórí Ẹgbẹ́ Tuntun
Àwọn Olórí ẹgbẹ́ òṣèlú 'All Progressives Congress APC' ti Ìpínlẹ̀ Kwara ní ọjọ́ Àbámẹ́ta, tún gbá àṣẹ láti tẹ̀síwájú ṣe olórí jákèjádò Ìjọba ìbílẹ̀ mẹ́rindínlógún pẹ̀lú ìfọwọ́sowọ́pọ̀ gbogbo ọmọ ẹgbẹ́.
Ìgbésẹ̀ náà, èyítí o fa àwọn…
Gómìnà Kano Gbóríyìn Fún INEC Àti Àwon Ilé-iṣẹ́ Ààbò Fún Ìdìbò Àlàáfíà
Gómìnà Ìpínlẹ̀ Kano, Abba Yusuf, ti yín Ìgbìmọ̀ Elétò Ìdìbò Olómìnira Orílẹ̀-èdè (INEC), àti àwọn ilé-iṣẹ́ ààbò fún iṣẹ́ àlàáfíà àti ìlànà tí ìdìbò abẹ́lé ní Ìpínlẹ̀ náà.
Ìyìn Gómìnà náà ní a gbé jáde nínú àtẹ̀jáde kán tí agbẹnusọ…
Wike Gbóríyìn Fún Ìdìbò Àlàáfíà Àti Ìwà Àwọn Olùdìbò
Mínísítà fún Agbègbè Olú-ìlú Nàìjíríà (FCT), Nyesom Wike, ti ṣàpèjúwe ìdìbò tí agbègbè Olú-ìlú Nàìjíríà gẹ́gẹ́ bí “àlàáfíà” ó sì gbóríyìn fún àwọn olùdìbò fún ìwà àlàáfíà.
Mínísítà náà gbóríyìn fún wọn lẹ́yìn tó ṣe àkíyèsí ìdìbò náà…
DG VON Ṣèbẹ̀wò Sí Gómìnà Ìpínlẹ̀ Nasarawa Fún Ìbáṣepọ̀ Ìròyìn Tó Lágbára
Olùdarí Àgbà fún Ilé Akéde Nàìjíríà (Voice of Nigeria VON), Mallam Jibrin Baba Ndace, ti ṣe ìbẹ̀wò sí Gómìnà Ìpínlẹ̀ Nasarawa, Abdullahi Sule, ní Ilé Ìjọba ní Lafia, èyí tó ń mú kí àjọṣepọ̀ láàrín àwọn oníròyìn àgbáyé àti ìjọba ìpínlẹ̀ náà…
Nàìjíríà Yóò Dá Ilé-ẹ̀kọ́ Ìṣègùn Àwọn Ológun Sílẹ̀
Ìjọba Nàìjíríà ti kéde ètò láti dá ilé-ẹ̀kọ́ ìṣègùn àti sáyẹ́ǹsì ìlera (Armed Forces College Of Medicine and Health Sciences AFCOM&HS) sílẹ̀ gẹ́gẹ́ bí apá kan nínú àwọn ìsapá láti mú kí ìtọ́jú ìlera lágbára síi láàrín àwọn ológun àti…
Mínísítà Fún Iṣẹ́ Nàìjíríà Bú-Ẹnu-Àtẹ-Lú Ìwà Ìbàjẹ́ Ni Òpópónà Èkó Sí Calabar
Mínísítà fún Iṣẹ́ ní Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, Dave Umahi, tí bú-ẹnu-àtẹ-lú àwọn ìwà ìbàjẹ́ àwọn ènìyàn ní òpópónà Èkó sí Calabar, Ó sí kìlọ̀ pé ọwọ́ òfin yóò mú àwọn tó ń hu ìwà ìbàjẹ́ náà.
Mínísítà ṣe ìkìlọ náà nígbà àyẹwò iṣẹ rẹ̀ ní…
Ètò Ààbò Tó lágbára Lo Wa Níbi Ìdìbò ìgbìmọ̀ Abuja Se Bẹ̀rẹ̀.
Àwọn olùgbé agbègbè olú ìlú àpapọ̀ Abuja jáde ní kùtùkùtù ní àwọn ibùdó ìdìbò káàkiri agbègbè náà ní ọjọ́ Sátidé, bí àwọn ilé iṣẹ́ ààbò ṣe ń ṣe àwọn iṣẹ́ tó pọ̀ láti rí i dájú wí pé ìdìbò ìgbìmọ̀ agbègbè náà wà ní àlàáfíà àti ní…