Browsing Category
ÌRÒYÌN YÀJÓ-YÀJÓ
This is a category for TRENDING NOW
Gómìnà Aiyedatiwa Ṣàlékún ààbò jákè jádò Ìpínlẹ̀ Ondo
Gómìnà ìpínlè Ondo, Lucky Aiyedatiwa, ti pàse fún àwon elétò ààbò láti túnbọ̀ lékún ìpààrà lórí ààbò jákè kádò àwọn agbègbè àti agbègbè aginjù látàrí ìkọlù Àgọ́ ọlọ́pàá kan ní ìjọba ìbílẹ̀…
Nàìjíríà kí orílẹ̀ èdè Haiti kú oríire àjọ̀dún ọdún méjìlé-lógún- lénígba…
Mínísítà Nàìjíríà fún ọ̀rọ̀ òkèèrè, Aṣojú Yusuf Tuggar, ti kí Mínísítà fún ọ̀rọ̀ òkèèrè orílẹ̀ èdè Haiti, Jean-Victor Harvel Jean-Baptiste, ìjọba àti àwọn ènìyàn Haiti, kú́ oríire àjọ̀dún òmìnira wọn.…
Igbákejì ÀàrẹTanzania pè fún ìfọwọ́sowọ́pọ̀ láti gbógun ti eebi
Igbákejì ÀàrẹTanzania, Philip Mpango ti pé fún ìṣọ̀kan àgbáyé láti kojú ebi àti ìpọ́njú, wípé orílẹ̀ èdè kan kò le dá ogun náà jà.
Gẹgẹ bi alaye kan ti o jade lati ile iṣẹ igbakeji Aarẹ ni ọjọ Ẹti, Mpango pe ipe…
Gómìnà Plateau kí àwọn aṣojú PDP káàbọ̀ fún àpèjọ Àríwá Àringbùngbùn
Gómìnà ìpínlẹ̀ Plateau, Caleb Mutfwang, ti gba àwọn aṣojú ẹgbẹ́ òṣèlú Peoples Democratic Party (PDP) láti Àríwá Àringbùngbùn lálejò fún oúnjẹ alẹ́ kí ìpàdé agbègbè ẹgbẹ́ láti yan àwọn ọmọ ẹgbẹ́ tuntun tó…
NAWOJ bẹ̀bẹ̀ fún ìrànlọ́wọ́ Hajj fún àwọn akọ̀ròyìn obìnrin
Alága obìnrin fún ẹgbẹ́ àwọn akọ̀ròyìn obìnrin ní Nàìjíríà (NAWOJ), Ẹlẹgbẹ́ Aisha Ibrahim, ti pè fún fífún àwọn akọ̀ròyìn obìnrin tí ń kọ̀ròyìn lórí ìrìn àjò mímọ́ lọ́dọọdún láyè láti darapọ̀ siṣẹ́…
Ààrẹ Tinubu kí Ayo Obe kú ọjọ́bìí pàtàkì ààdọ́rin ọdún
Ààrẹ Bola Tinubu ti ki olokiki agbẹnusọ alatilẹyin tiwantiwa ti o tun jẹ agbẹjọro, Omidan Ayo Obe, kú àjọ̀dún ọjọ́bìí ààdọ́rin ọdún.
Ile iṣẹ Ààrẹ sọ ninu alaye kan pe Aarẹ Tinubu gboriyin fun amofin naa fun iṣafihan deede fun…
NELFUND pín iye owó tó lé ní Bílíọ́nù mẹ́rìndínlọ́gọ́ta Náírà fún ẹ̀yáwó akẹ́kọ̀ọ́
Àjọ tí ń rísí owó yíyá fún ẹ̀kọ́ ní Nàìjíríà (NELFUND), ti kéde pínpín iye owó tó lé ní Bílíọ́nù mẹ́rìndínlọ́gọ́ta Náírà láìgba èlé fún àwọn ilé ẹ̀kọ́ gíga tíjọba jákèjádò orílẹ̀-èdè láti bí…
Àjọ NELFUND Bẹ̀rẹ̀ Pinpin Owó Àlàkalẹ̀ Ti Oṣù Kẹrin
Àjọ Nigerian Education Loan Fund (NELFUND) ti bẹ̀rẹ̀ pinpin Owó ẹ̀yá àlàkalẹ̀ ti Oṣù Kẹrin ọdún 2025 fún àwọn akẹ́kọ̀ọ́ tó peregede fún un jákèjádò Nàìjíríà.
Àkọsílẹ̀ láti ọdọ Alakoso àjọ Strategic Communications owó náà, Ìyáàfin Oseyemi…
NGO ní òun ti ní ipa lórí àwọn ènìyàn méjìlé-lọ́gbọ̀n Mílíọ́nù ní abala ìtọ́jú…
Ilé iṣẹ́ tí kìí ṣe tìjọba kan, Nigeria Solidarity Support Fund, NSSF, ti sọ pé òun ti ní ipa lórí àwọn ènìyàn méjìlé-lọ́gbọ̀n Mílíọ́nù ní ọdún mẹ́rin tí òun ti ń ṣiṣẹ́ ní abala ìtọ́jú ìlera lórílẹ̀-èdè.…
Olùdíje Gómìnà fún ẹgbẹ́ LP Anambra bẹnu àtẹ́ lu pípa Agbẹjọ́rò
Olùdíje Gómìnà fún ẹgbẹ́ òṣèlú Labour (LP), ti ìpínlẹ̀ Anambra, Ọ̀gbẹ́ni George Moghalu, ti bẹnuàtẹ́ lu ìṣẹ̀lẹ̀ aburú pí́pa Ààrẹ- gbogbogbòò agbègbè Aguleri ti agbègbè ìjọba ìbílẹ̀ Gusu Anambra, Ọ̀gbẹ́ni Ifeanyi…