Browsing Category
ÌRÒYÌN ILẸ̀ ÀFÍRÍKÀ
This is a category for Africa news
ìgbìmọ̀ Orílè-èdè Zimbabwe Ti Tẹ síwájú Ètò Láti Fẹ Òfin Ààrẹ Mnangagwa Lójú sí.
Igbimọ̀ Orílẹ̀-èdè Zimbabwe ti fọwọ́ sí àtúnṣe òfin tí yóò jẹ́ kí Ààrẹ Emmerson Mnangagwa wà ní ipò títí di ó kéré tán ọdún 2030, èyí tí ó lè tún ètò ìṣèlú orílẹ̀-èdè náà ṣe, tí yóò sì mú kí àríyànjiyàn pọ̀ sí i lórí ìṣàkóso tiwantiwa.…
Mínísítà Uganda Kan B’ẹnú Àtẹ Lú Ìkọlù Àwọn Ológun Kan
Mínísítà Ìròyìn Uganda, Chris Baryomunsi, tí b'ẹnú àtẹ lù ìkọlù àwọn ológun sí ilé alátakò ìjọba Bobi Wine ní oṣù tó kọjá.
Ó sọ pé olóṣèlú olórin tẹ́lẹ̀ náà kò dá ẹ̀ṣẹ̀ kankan, ó sì ní òmìnira láti padà síbẹ̀.
Wine ti sá sí…
Oshodi Fí Ìdùnnú Rẹ̀ Hàn Lórí Ìṣọ̀kan Ilẹ̀ Áfíríkà Nípasẹ̀ Tẹ́nìsì Orí Tábìlì
Bí ìdíje tẹ́nìsì orí tábìlì tilẹ̀ Áfríkà 2026 (ITTF Africa Cup 2026) ṣe bẹ̀rẹ̀, Ààrẹ Ẹgbẹ́ Tẹ́nìsì Orí Tábìlì ti Áfíríkà (ITTF Africa), Wahid Enitan Oshodi, ti yin ìdíje náà ní Libya gẹ́gẹ́ bí ìṣẹ̀lẹ̀ pàtàkì kan tó kọjá eré ìdárayá, tó ń…
Orílè-èdè South Africa Ṣe ìfilọ́lẹ̀ Abẹ́rẹ́ Àjẹsára Ti Ẹsẹ ati Ẹnu Láti Dènà ilosoke Ìkolù Àìsàn
Gúúsù Africa ti kede abẹ́rẹ́ ajesara ẹsẹ ati ẹnu akọkọ rẹ ni ogun ọdun bi o ti n wa lati mu iṣelọpọ awọn iwọn lilo ajesara agbègbè pọ si lati ja ajakale-arun ti o buru julọ ni orilẹ-ede náà ni ọpọlọpọ ọdun.
Ẹsẹ-ati-ẹnu jẹ arun ọlọjẹ ti…
Adarí alátakò South Africa sún sẹ́gbẹ̀ẹ́
Adarí Democratic Alliance (DA), John Steenhuisen ti kéde pé òun kò ní díje ìbò fún ìgbìmọ̀ ẹgbẹ́ lápapọ̀ ní oṣú kẹrin, ìpinnu tó fa ìṣiyèméjì sí ìṣọ̀kan ìjọba àpapọ̀ orílẹ̀-èdè (GNU).
Steenhuisen, to ti ṣadari…
Nàìjíríà Tún Ìpinnu Rẹ̀ Ṣe Láti Mú Ìrọ̀rùn Bá Iṣòwò
Mínísítà fún Ìròyìn àti Àlàyé Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, Mohammed Idris, ti tún ìpinnu Ìjọba Àpapọ̀ ṣe láti mú ìrọ̀rùn bá ṣíṣe iṣòwò, àìsí ìrújú kan àti àtúnṣe àwọn ilé-iṣẹ́ ìṣòwò, ó ṣàpèjúwe ìfọwọ́sowọ́pọ̀ tó munadoko láàárín àwọn ilé-iṣẹ́…
Wọn Ti Pá ‘Seif Gadhafi’ Ọmọ Ààrẹ Orílẹ̀-èdè Libya Tẹ́lẹ̀ Rí
Wọn tí pá Seif al-Islam Gadhafi, ọmọ Moammar Gadhafi Ààrẹ Orílẹ̀-èdè Libya Tẹ́lẹ̀, ní ìlú Zintan, gẹ́gẹ́ bí àwọn aláṣẹ Libya ti sọ.
Wọn kò tíì kéde ipò ikú rẹ̀ ṣùgbọ́n àwọn oníròyìn ń ròyìn pé àwọn agbebọnrin kan pa á nílé rẹ̀.
A…
Àjọ UN Rán Ikọ̀ Adágun Dúró Lọ Sī Congo
Àjọ ikọ̀ alalaafia, United Nations peacekeeping mission ní Congo yoo ran ikọ̀ akọkọ rẹ láti mojuto idawọ́ ogun dúró láàrin ìjọba Congo àti ikọ̀ ọlọtẹ
AFC/M23 laipẹ ọjó die to n bọ̀. Minisiri ilé òkèèrè ti Quatar ló sọ èyí ní ọjó…
Ilé Ìfowopamọ́ Àgbáyé Gbé Ogún Mílíọ̀nù Dọ́là Kalẹ̀ Fún Àtunse Omí Yalé Ní Orílè-èdè Mozambique
Ilé Ifowopamọ Àgbáyé ti gbé Ogún Mílíọ̀nù Dọ́là Kalẹ láti ṣe iranlọwọ fún Orílè-èdè Mozambique Látàrí Omí yalé ti o n báwon Fira láti Ọdun to kọja
Nínú ọ̀rọ̀ tó Mínísítà fò jáde, O wí pè owó náà yóò jẹ ìrànlọ́wọ́ nla láti yanjú ijamba náà…
CAF Dá Olùkọ́ni Senegal Dúró Fún Rògbòdìyàn Ìdíje AFCON
CAF ti dá olùkọ́ni Senegal Pape Thiaw dúró fún ifẹsẹwọnsẹ márùn-ún, wọ́n sì tún bu owó ìtanràn ẹgbẹ̀rún lọ́nà ọgọ́rùn-ún dọ́là ($100,000) fún lórí ìwà tó kù díẹ̀ kaato tó wú lẹ́yìn tó sọ fún àwọn agbábọ́ọ̀lú rẹ̀ pé kí wọ́n kúrò lórí pápá…