Browsing Category
ÌRÒYÌN ILẸ̀ ÀFÍRÍKÀ
This is a category for Africa news
Ààrẹ Tinubu Ṣèpàdé Pẹ̀lú Paul Kagame Ní Paris
Ààrẹ Bola Tinubu ti ṣé ìpàdé bóǹkẹ́lẹ́ pẹ̀lú Ààrẹ Orílẹ̀-èdè Rwanda, Paul Kagame, ní Paris, France, níbi tí àwọn olórí méjèèjì ti jíròrò àwọn ọrọ àgbáyé àti tí Áfíríkà.
Ìpàdé bóǹkẹ́lẹ́ náà jẹ́ ìgbà àkọ́kọ́ ti Ààrẹ Tinubu tí yóò…
Agbábọ́ọ̀lù Gueye Jẹ́ kí Ikọ̀ Senegal Wọ Ipele Kẹta Tó Kángun Sí Àsekágbá Ìdíje AFCON
Ògbóntàrigi agbábọ́ọ̀lù ní ipò àárín fún ikọ̀ Senegal, Pape Gueye sọ bọ́ọ̀lù ní igbà méjì sínú àwọ̀n nígbà ti ikọ̀ Senegal jà raburabu látẹ̀yìn wá láti lu ikọ̀ Sudan ní ayò mẹ́ta sí oókan(3-1) ní ìpele kẹta tó kángun sí àsekágbá ìdíje…
Malawi Fagilé Owó Ilé-ẹ̀kọ́ Gírámà
Ìjọba Malawi tí kéde pé a tí fagilé owó pàtàkì ní àwọn ilé-ẹ̀kọ́ gírámà, láti ọjọ́ kìíní oṣù kìíní ọdún 2026, ní ìgbésẹ̀ kan tí a gbé kalẹ̀ láti mú kí ọ̀nà ẹ̀kọ́ gbòòrò sí i jákèjádò Orílẹ̀-èdè.
Ilé-iṣẹ́ Ẹ̀kọ́ jẹ́rìí sí i pé a ti…
’Super Eagles’ Bẹ̀rẹ̀ Ìgbaradì Fún Ìpele Oníkọ̀ Mẹ́rìndínlógún Tí AFCON 2025
Bí Super Eagles ṣe ń múra sílẹ̀ fún ifẹsẹwọnsẹ wọn nínú ìdíje bọ́ọ̀lù Adúláwọ̀ "African Cup of Nations" (AFCON) ní ìpele oníkọ̀ mẹ́rìndínlógún pẹ̀lú Mozambique ní ọjọ́ karùn-ún oṣù kìíní, ọdún 2026, àwọn òun márùn-ún wọ̀nyí ló ń ṣẹlẹ̀ sí…
Nàìjíríà kí orílẹ̀ èdè Haiti kú oríire àjọ̀dún ọdún méjìlé-lógún- lénígba…
Mínísítà Nàìjíríà fún ọ̀rọ̀ òkèèrè, Aṣojú Yusuf Tuggar, ti kí Mínísítà fún ọ̀rọ̀ òkèèrè orílẹ̀ èdè Haiti, Jean-Victor Harvel Jean-Baptiste, ìjọba àti àwọn ènìyàn Haiti, kú́ oríire àjọ̀dún òmìnira wọn.…
Gómìnà Zulum Gbàlejò Ìpàdé Àsà Ti Kanem-Borno
Gomina ipínlẹ̀ Borno, Babagana Umara Zulum, ti gbàlejò ìpàdé ọ̀gọ̀rọ̀ ẹgbẹgbẹ̀run ẹ̀yà ènìyàn Kanuri ó kéré tán orílẹ-èdè mẹ́wàá láti Ilẹ̀ Adúláwọ̀ tó wá síbi ìpàde àṣà ti Kanem-Borno tó wáyé ní ìlú Maiduguri.
Ìpàdé náà ṣe àgbájọpọ̀…
Wọ́n Kọ̀ Láti Gbá’dúró Alátakò Ìjọba Ùgándà Kizza Besigye
Lẹ́yìn ọdún kan tí wọ́n ti mú un, ilé ẹjọ́ gíga orílẹ̀-èdè náà ti kọ̀ láti gbá òní'dúró alátakò Ìjọba Ùgándà Kizza Besigye kúrò nínú túbú.
Wọ́n ti fi ẹ̀sùn ìṣọ̀tẹ̀ kan Besigye nítorí pé ó gbèrò láti fi agbára mú ààrẹ Yoweri…
Igbákejì ÀàrẹTanzania pè fún ìfọwọ́sowọ́pọ̀ láti gbógun ti eebi
Igbákejì ÀàrẹTanzania, Philip Mpango ti pé fún ìṣọ̀kan àgbáyé láti kojú ebi àti ìpọ́njú, wípé orílẹ̀ èdè kan kò le dá ogun náà jà.
Gẹgẹ bi alaye kan ti o jade lati ile iṣẹ igbakeji Aarẹ ni ọjọ Ẹti, Mpango pe ipe…
Orílẹ̀-èdè Algeria Yóò Rí Bílíọ̀nù Mẹ́ta Dọ́là Owó Ẹ̀yá Gbà Láti Ọ̀dọ̀ Báǹkì Ìdàgbàsókè Ìsìláàmù
Ààrẹ Banki Idagbasoke Isilaamu - "Islamic Development Bank" Muhammad Sulaiman Al Jass ti sọ pé Orílè-èdè Algeria yoo ri Biliọnu Mẹta Owó dọ́là ya laarin odun mẹta tẹ̀léra lati fi ṣe àwọn àkànṣe iṣẹ ìdàgbàsókè.
Ààrẹ…
WHO Yàn Olùdarí Àgbègbè Túntún Tí Áfíríkà
Àjọ Àgbáyé fún Ìlera (World Health Organization WHO) tí kéde yíyan tí Ọ̀jọ̀gbọ́n Mohamed Janabi gẹ́gẹ́bí Olùdarí túntún fún Ẹkùn Áfíríkà tí WHO.
Yíyan náà ni a ṣé l'àkókò àpéjọ pàtàkì kán tí Ìgbimọ Àgbègbè WHO fún Áfíríkà, tó wáyé ní…