Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Gbá Látí Só Ìbáṣepọ̀ Wọ́n Pẹ̀lú Iran Lé dọin-dọin
Ààrẹ Muhammadu Buhari tí fí dá Ìgbákejì Ààrẹ orílẹ̀-èdè Iran lójú pé òún ṣetán láti sọ d'ọtun ìbáṣepọ̀ tó wà lọwọ́ pẹ̀lú Orílẹ̀-èdè Iran
Ààrẹ Buhari sọ èyí lásìkò tí Ìgbákejì Ààrẹ orílẹ̀-èdè Iran, Mohsen Mansouri ṣé àbẹwò sí níbí ìpàdé…