Take a fresh look at your lifestyle.

Ètò Ẹ̀yawó Àwọn Ọmọ Ilé-ìwé Tí 2024/2025 Yóò Bẹ̀rẹ̀ Ní Oṣù Kejì, Ọdún Yìí

Ètò ẹ̀yawó àwọn akẹ́kọ̀ọ́ Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà 'Nigeria Education Loan Fund NELFUND', ní wọ́n yóò faye gbá ìforúkọsílẹ̀ fún tí ọdún 2024/2025 yóò bẹ̀rẹ̀ ọjọ́ kejìlélogún, Oṣù Kejì, Ọdún 2025. ‎ ‎ Wọ́n tún sọ pé tí ọdún 2023/2024 ní yóó wá…

Ìyàwó Ààrẹ Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Ṣé Ìlérí Àtìlẹ́yìn Fún Àwọn Obìnrin Àti Ọdọ

Àyá Ààrẹ Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, Oluremi Tinubu sọ pé òún tí pinnu látí ṣé ìpolongo, koriya àti ìdásílẹ̀ àwọn àjọṣepọ̀ tí yóò fún àwọn obìnrin àti àwọn ọdọ Nàìjíríà ní àgbàrá láti ṣiṣẹ́. ‎ ‎ O n sọrọ yíi l'àkókò Àpéjọ Gbogbogbò tí…

Àwọn Aṣojú Ìjọba Ilẹ̀ Áfíríkà Kẹ́dùn Olóògbé Nujoma Pẹ̀lú Nàmíbíà

Ìgbìmọ̀ Àwọn aṣojú orílẹ̀-èdè Áfíríkà tí darapọ̀ mọ́ àwọn yòókù lágbayé láti ṣọfọ ikú Sam Nujoma, Ààrẹ àkọkọ́ ní Orílẹ̀-èdè Namibia lẹyìn òmìnira, tó kú ní ẹní odún márún dín lọgọ́rùn (95). ‎ ‎ Nujoma jẹ́ olókìkí ajá-fẹtọ́-ọmọnìyàn,…

FUHSI VC Rọ́ Àwọn Ọmọ Ilé-ìwé Rẹ̀ Látí F’akọyọ Lórí Ètò Ẹ̀kọ́ Wọ́n Pẹ̀lú Ìwà Réré

‎ Ìgbákejì Adarí (VC) tí Ilé-ìwé gíga 'Federal University of Health Sciences, Ila-Orangun (FUHSI)', Ìpínlẹ̀ Osun, Ọ̀jọ̀gbọ́n Akeem Lasisi tí rọ́ àwọn ọmọ ilé-ìwé rẹ̀ túntún látí kọ́ ẹ̀kọ́ àti ìhùwàsí tó dára. ‎ ‎ Ọ̀jọ̀gbọ́n Lasisi sọ pé…
button