Take a fresh look at your lifestyle.

Olóyè Pàtàkì Ni Ile Ẹjọ Gíga  Jùlọ Rọ Awon Adájọ Láti Se Ìdájọ Pèlú Àánú.

Olóyè Pàtàkì  ni ilé ẹjọ́ gíga jùlo ni Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, Kabir Akanbi ti rọ àwọn adájọ kàkàkí Orílè-èdè Nàìjíríà láti ṣe ìdájọ pèlú Àánú lójú. Nígbà tí o ṣe Ẹgbẹ́ àwọn adájọ ti ìlú Abuja ( NAJUC) se ìbẹ̀wọ̀ sí Akanbi ni o ti rọ wọn…

Àwọn Òṣìṣẹ́ Elétò Aláàbò Dènà Àdó Olóró Láti Du Gbámú Ni Ìpínlẹ̀ Anambra.

Àwọn elétò òṣìṣẹ́ aláàbò nì ìpínlẹ̀ Anambra ti ba ìmọ̀ àwọn ènìyàn oníṣe laabi jẹ latari bi wọn ṣe dènà àdó olóró láti bí gbámú ni ìpínlẹ̀ náà  Lásìkò tí wọn ṣe àyẹwò sí ìbi ifarapamo àwọn ènìyàn oníṣe laabi náà tó wà ni ìjọba ìbílẹ̀…

Ètò Ẹ̀kọ́: Ìyàwó Ààrẹ Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Rẹmi Tinubu Bèrè Anfààní Ẹ̀kọ́ Ọfẹ Fún Àwọn Ọ̀dọ́.

Ìyàwó Ààrẹ Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Oluremi Tinubu, sọ wí pé oun ṣiṣe lórí bí ètò ẹ̀kọ́ ọfẹ yóò ṣẹ wa fun àwọn ọ̀dọ́ Nígbà tí o ń ba aláṣẹ ilé iṣé MERCK Foundation sọ̀rọ̀, ilé iṣé ti o jẹ aláàdáni láti Orílẹ̀-èdè German nígbà tí wọn ṣe àbẹ̀wò…

Ìpínlẹ̀ Kaduna: Àwọn Ènìyàn Ìpínlẹ̀ Náà Parapò Láti Ṣe Àjoyọ́ Ọjọ́ Àlàáfíà.

Àwọn ará agbègbè ìpínlẹ̀ Kaduna ti pejo láti ṣe àfihàn ifẹ, irepo àti ìsọkan láàrin ara wọn ní ojọ́ kerindinlogun oṣù kàrún ọdún, 2025. Ààrẹ ẹgbẹ́ àlàáfíà ti onigbagbọ wọn pẹ ni PRRFON  alàgbà Buru kí àwọn ènìyàn tó jẹ Musulumi káàbò sí…
button