Ẹgbẹ́ Àwọn Akékòó Gbóríyìn Fún Ààrẹ Tinubu Fún Atilẹyin Rẹ Lórí Ètò Ẹ̀kọ́.
Ẹgbẹ́ àwọn akékòó ni Orílè-èdè Nàìjíríà (NANS) tí gbóríyìn fún Ààrẹ Bola Ahmed Tinubu fún èròngbà rere nípa ìdàgbàsókè Ẹ̀kọ́.
Ààrẹ fún ẹgbẹ́ NANS Lucky Emonife lo ṣe Igboriyin náà fún Ààrẹ ni ọjọ́rú ní ìlú Abuja
Emonife sọ wí pé ìwà…