Take a fresh look at your lifestyle.

Hajj Ọdun 2022: FCTA Ṣètò afikún owó àsansílẹ̀ fún Àwọn Arìnrìn àjò mímọ́ Hajj

Eyitayọ Fauziat Oyetunji

0 288

Àjọ àwọn mùsùlùmí ti ìṣàkóso ìjọba àpapọ̀ olú ìlú Nàìjíríà, FCTA, ti fún àwon arìnrìn àjò mímọ́  láti se Hajj odun yìí ní orílẹ̀-èdè Saudi Arabia títí di ọjọ́ kẹtàlá oṣù karùn-ún láti fi kún owó àsansílẹ̀ tí wọ́n san, kí ìgbìmọ̀ Hajj orílẹ̀-èdè tó kéde owó Hajj gangan.

Oludari Igbimọ, Mallam Muhammad Nasiru Danmallam, sọ eyi lasiko ti o n ba awọn to fẹ rinrin ajo sọrọ lakoko ipele keji  ẹkọ ati iṣalaye ti o waye ni ipari ose ni Hajj Transit Camp ti o wa  ni ilu Abuja.

Danmallam ṣalaye pe sisan kun owo irinajo Awọn aririn ajo  yoo jẹ ki Igbimọ ṣeto ikọrukọ silẹ  fun awọn arinrin ajo lọ si Saudi Arabia.

Leave a Reply

Your email address will not be published. Required fields are marked *

button