Take a fresh look at your lifestyle.
Browsing Category

KÓKÓ INÚ ÌRÒYÌN

This is a category for featured story

Ayẹyẹ Ọdún Ajinde: Ẹ Gbé Ìgbé Ayé Tó Bu Ọlá Fún Ọmọnìyàn – Aláàfin Ọ̀yọ́

Aláàfin Ọ̀yọ́, Ọba Abímbólá Akeem Owoade I, ti gba ọmọ orilẹ èdè Nàìjíríà níyànjú láti pawọ́pọ̀ gbógun ti ìtàjẹ̀sílẹ̀ àti gbogbo ẹni yìówù tó sọ ará rẹ̀ di ọ̀tá ìlú tó n pa ènìyàn ni ìpakúpa. Ọba Owoade, ẹni tó korò ojú si ìwà ìpànìyàn…

Ìjọba Kéde Ọjọ́ Kejìdínlógún Àti Ọjọ́ Kọkànlélógún Osù Kẹrin Gẹ́gẹ́bí Ọjọ́ Ìsinmi Lẹ́nu Iṣẹ́ Fún…

Ìjọba orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ti kéde Ọjọ́ Kejìdínlógún àti Ọjọ́ Kọkànlélógún Osù Kẹrin ọdún 2025 gégébí Ọjọ́ ìsinmi lẹ́nu Iṣẹ́ láti ṣe pọ̀pọ̀sìnsìn ọjọ́ Ẹtì rere àti ọjọ́ Ajé Àjíǹde bákannáà. Mínísítà fún Ọ̀rọ̀ Abẹ́lé , Dókítà Tunji-Ojo lo…

Àjọ UNICEF Pèsè Mílíọ̀nù Mẹ́ẹ̀dógún Owó Ìrànwọ́ Fún Ìpínlẹ̀ Kaduna,Kebbi Àti Bauchi

Àjọ UNICEF ti pèsè Mílíọ̀nù Mẹ́ẹ̀dógún Owó Ìrànwọ́ fún Ipinlẹ Kaduna,Kebbi, àti Bauchi ní ọnà láti ró ijọba àti agbègbè lágbára fún ìpèsè ohun ètò tó jẹ mọ́ ìbálòpọ̀, ètọ́ ọmọnìyàn àti ohun ètò ìlera. Nígbàtí ó ń sọ̀rọ̀ níbi ètò Ọlọ́jọ́…

Ètò Ìsúná Owó Fún Ètò Ọ̀gbìn Ti Ọdún 2025 Ní Ìpínlẹ̀ Bauchi Kéré Jọjọ- Àwọn Àgbẹ̀…

Ìgbìmọ̀ tí ń wòye sí ètò ìsúná owó ní Ìpínlẹ̀ Bauchi ti korò ojú látàrí bí ètò ìsúná ètò ọ̀gbìn ọdún 2025 se kéré jọjọ Adarí ìgbìmọ̀ náà Arábìnrin Tabawa Atiku ni ó sọ ọ̀rọ̀ náà nígbà…

Àpérò Ẹlẹ́ẹ̀keje Ìgbìmọ̀ Àwọn Ọba Alayé Àréwá Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Gbérasọ

Látàrí bí wàhálà òhun ìdààmú àwọn alákatakítí Boko Haram se ń pọ̀ si ní apá Arewa Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, papàá jùlọ Ìpínlẹ̀ Borno àti Gúsù Ilà Oòrùn, ìgbìmọ̀ àwọn Ọba Alayé apá Arewa ti pe ìpè fún…

Ààrẹ Tinubu Wá Ojútùú Sí Wàhálà Àti Ìpànìyàn Tí Ó Ń Wáyé Ní Ìpínlẹ̀ Plateau

Ààrẹ Bọla Ahmed Tinubu ti pè fún fífi òpin sí wàhálà àti rúkè-rúdò tí ó ń sẹlẹ̀ ní ìpínlẹ̀ Plateau, ó ké sí àwọn Ọba Alaye, olórí Ẹ̀sìn, Olósèlú jákè-jádò Ìpínlẹ̀ náà láti fọwọ́sowọ́pọ̀ lójúnà àti…

Ìgbésẹ̀ Wáyé láti Se Ètò Mọ̀ọ́kọ-mọ̀ọ́kà, Iṣẹ́ Ọwọ́ Fún Àwọn Tí Ó Ní Ìpèníjà Ara…

Àjọ Ọmọ lẹ́yìn Kírísítì kan pẹ̀lú ìfọwọ́sowọ́pọ̀ àwọn ènìyàn àgbègbè Taimako ti se ìfilọ́lẹ̀ àkànṣe iṣẹ́ kan èyí ti ó ní àfojúsùn ìdàgbàsókè ètò ẹ̀kọ́ àti iṣẹ́ ọwọ́ fún àwọn tí ó ní ìpèníjà ara ní…

Àjọ CAA Yan Afunfèrè Rẹfirí Ọmọ Nàìjíríà Fún Ìdíje Tí Ọjọ́ Orí Àwọn Akópa Kò Kọjá Ogún Ọdún Ní…

Àjọ Confederation of Africa Athletics (CAA) ti yan Omatseye Nesiama tó jẹ́ adarí àjọ Athletics Federation of Nigeria (AFN) nígbà kan ri gẹgẹbí afunfèrè Rẹfirí  ìdíje alápapọ̀ ẹlẹ́ẹ̀kẹta Adúláwọ̀ ti Ọjọ́ orí àwọn akópa kò kọjá Ogún Ọdún ti…

Makinde Ke Sí Ọmọ Orílẹ̀ Èdè Nàìjíríà Láti Wá Dá Okòwò Sílẹ̀ Ní Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́

Gómìnà Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́, Seyi Makinde ti ké sí ọmọ Orílẹ̀ Èdè Nàìjíríà láti wá da okòwò sílẹ̀ ní Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́, nígbà tó fìdí rẹ̀ múlẹ̀ pé Ìpínlẹ̀ náà wà lójú iṣẹ́ lójúnà àti mú kí ọrọ̀ àjé gbèru síi nípasẹ̀ ètò ìgbáyé-gbádùn. Makinde ló…
button