Browsing Category
KÓKÓ INÚ ÌRÒYÌN
This is a category for featured story
Pípa Àwọn Ológun Tó Lọ Ṣètò Bí Àlàáfíà Yóò Se Jọba Burú Jáì – Mínísítà Ètò Ààbò
Mínísítà ètò ààbò, Muhammed Badaru Abubakar ati Mínísítà ètò ààbò ipinle, Bello Matawalle ti sọ pe bi won se pa awọn ologun ti won lo petú sí ija ni ipinle Delta ko je itẹwọgba, o buru jai.
Bí àwọn Mínísítà náà se sọ, ìkọ̀lù…
Ìdíje Ilẹ̀ Adúláwọ̀: Akọ́ni-mọ̀ọ́gbá Flying Eagles Sàlàyé Ìdí Tí Wọn Se Fìdírẹmi
Akọ́ni-mọ̀ọ́gbá Flying Eagles, Ladan Bosso, ti salaye bi ikọ̀ rẹ se já danu nibi idije eleeketala ti ile Adulawo wipe aito asiko lati gbaradi ati lati wa awọn irawọ agbaboolu lo fa.
Ìrètí ikọ̀ Naijiria lati peregede sí ipele to…
Àjọ Kan Pè Fún Gbígbé Lọsílẹ̀ Èlé Orí Owó Fún Àjọ MSMEs
Àjọ National Institute of Credit Administration ti sọ pe ọpọ yanturu owo yiya pẹlu ele ori owo kekere ati irọrun sisan re padà yóò ràn igberu Small and Medium scale Enterprises lọwọ.
Nínú akọsilẹ kan, ọ̀gá àgbà àjọ NICA, Kòfẹ́sọ̀…
KCEE Gbé Orin Tí Àkọ́lé Rẹ̀ Jẹ́ ‘Ojapiano’ Jáde
Irawọ akọrin ọmọ Nàìjíríà - KCEE ti gbé orin ti akọle rẹ je ‘Ojapiano' sita. O gbe orin yìí sita pẹlu ajumọṣe ile iṣẹ orin olokiki lati ṣe àtúnpòpọ̀ orin ẹlẹ́yọkan náà. Wọn ti kọkọ gbe orin yii sita lati owo - Jaysynths, kí òun to…
Ìràwọ̀ Iwobi Àti Bassey Tàn Bí ikọ̀ Fulham Se Lù Ikọ̀ Tottenham
Ìràwọ̀ agbaboolu ọmọ Nàìjíríà, Alex Iwobi tan, Calvin Bassey náà sì gba ipò ẹ̀yìn wuni bi ikọ̀ Fulham se lù Tottenham Hotspur bi ẹni lù Igbo ni ayo mẹta sí odo (3-0)ni ti Lígìì Premier ni Craven Cottage ti ìlú London, orílẹ̀-èdè…
Italy, Ìgbìmọ̀ EU yóò buwọ́lu àdéhùn ìfọwọ́sowọ́pọ̀ pẹ̀lú Egypt
Adarí orílẹ̀-èdè Italy, Giorgia Meloni ti sọ pé òun yóò wà ní Cairo, ní ọjọ́ Àìkú láti buwọ́lu àdéhùn láàrin Yúróópù àti Egypt fún àjọṣepọ̀ àti ìdàgbàsókè kannáà sí àjọsọ tí Italy ṣe pẹ̀lú Tunisia ní…
Oúnjẹ tí èròjà rẹ̀ pé yóò dènà àárẹ̀ ọmọdé, Onímọ̀ oúnjẹ
Onímọ̀ oúnjẹ kan, Ìyáàfin Chioma Ezegwe, ti sọ pé fífún ọmọ ní èròjà oúnjẹ tó pé, níwọ̀n tún wọ̀n sì yóò ràn ọmọ lọ́wọ́ láti ṣe dáradára nínú ẹ̀kọ́ rẹ̀ tí kò sì ní jẹ́ kó máa ní ìdágúnlẹ̀ ààrùn…
Kwara: Ẹgbẹ́ pín ohun èlò oúnjẹ fún àwọn ọmọ ìlú tó nípa lára
Ẹ̀ka Ìṣọ̀kan àwọn ìpínlẹ̀ ti Ẹgbẹ́ Ìlọsíwájú Àwọn ọmọ Ìlọrin (IEDPU), ti ṣe ìfilọ́lẹ̀ ìpolongo oúnjẹ pínpín ọdọọdún rẹ̀, èyí tí wọ́n ń ṣe láti ṣe àfihàn ìfọkànsí wọn ní ṣíṣe ìrànlọ́wọ́ fún àwọn ọmọ ìlú tó…
Ìjọba Nàìjíríà dárò ikú Aṣojú, Rashid Bawa
Ìjọba Nàìjíríà ti dárò pẹ̀lú ìjọba àti àwọn ènìyàn Ghana lórí iku H.E. Rashid Bawa, Aṣojú orílẹ̀-èdè Ghana sí Nàìjíría.
Eleyi wa ninu alaye kan ti Francisca Omayuli, agbẹnusọ fun ile iṣẹ ijọba apapọ ti n ri si…
Àwọn ọmọ ológun Nàìjíríà mu àwọn oníjàgídíjàgan mẹ́rin balẹ nínú ìkọlù
Àwọn ọmọ ológun Nàìjíríà pa àwọn oníjàgídíjàgan mẹ́rin nínú isapamọ ati ikọlu ti o waye ni ipinlẹ Kaduna ati Katsina.
Alaye kan lati ọdọ Adari eto ibaraẹniṣepọ awọn ara ilu ti ologun, Ajagun Onyema Nwachukwu, sọ lasiko iṣẹ…