Take a fresh look at your lifestyle.
Browsing Tag

#2023_Orílẹ̀_èdè_Nàìjíríà_Ṣe_Ìpinnu

Ẹ̀kúnrẹ́rẹ́ Ọ̀rọ̀ – Ọ̀rọ̀ ìdágbére Láti Ẹnu Ààrẹ Muhammadu Buhari, Ààrẹ Orílẹ̀-Èdè…

Ẹ̀yin ènìyàn mi lórílẹ̀ èdè Nàìjíríà, àti àwọn tó ń gbé káàkiri àgbáyé. Mò ń bá a yín sọ̀rọ lóní, èyi tó jẹ́ iṣẹ́ mi tí ó gbẹ̀yìn gẹ́gẹ́ bi Ààrẹ Ìjọba tiwa-n-tiwa tí a yàn sípò gẹgẹ bi ààrẹ orilẹ-ede…

Ẹgbẹ́ Òṣèlú APC Jáwé olúborí Ní Ìjoba ìbílẹ̀ Opobo/Nkoro, Ìpínlẹ̀ Rivers

Egbe Òṣèlú APC ti yege ní Ìjọba Ìbílẹ̀ Opobo/Nkoro, Ìpínlẹ̀ Rivers nínú ìbò ààrẹ tó wáyé lọ́jọ́ Àbámẹ́ta tó kọjá. Ó jẹ́ agbègbè ibi ti Olùdíje Ẹgbẹ́ Òṣèlú PDP, Siminialaye Fubara ti wá. Ẹgbẹ́ Òṣèlú APC borí pẹ̀lú ìbò 5701 , Ẹgbẹ́ Òṣèlú…

Kíkà èsì ìbò Ààrẹ wá sí òpin ní Ìpínlẹ̀ Èkìtì, wọ́n gbóríyìn fún àṣeyọrí rẹ̀

Kika èsì ìbò Ààrẹ wá sí òpin ni Ìpínlẹ̀ Èkìtì, eleyii tó wáyé ní olu-ile iṣẹ́ Àjọ Elétò Ìdìbò INEC tí Ìpínlẹ̀ Èkìtì. Lọ́jọ́ Àìkú tí ṣe ọjọ́ kẹrìndínlọ́gbọ̀n oṣù kejì ọdún 2023, ọjọ́ kejì lẹ́yìn ọjọ́ ìdìbò gbogboogbò ni wọ́n kà àwọn èsì…

Ètò Ìdìbò 2023: Ilé iṣé tí kì í ṣe ti Ìjọba Gbósùbà Fún Àwọn Ọmọ Ológun orílẹ̀-èdè Nàìjíríà.

Ilé iṣé Ilé iṣé tí kì í ṣe ti Ìjọba tó ń mójútó ọ̀rọ̀ ará ìlú láti ètò ìdìbò ti Gbósùbà fún àwọn ọmọ ogun orílẹ̀-èdè Nàìjíríà fún akitiyan wọn nínú ìdìbò ààrẹ àti adarí ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin tó wáyé ni ọjọ́ àbámẹ́ta. Ilé iṣé náà sọ wí…

Gómìnà Ìpínlẹ̀ Èkìtì gbóríyìn fún iṣẹ́ akíkanjú Àjọ INEC fún ẹ̀rọ BVAS

Gómìnà Ìpínlẹ̀ Èkìtì, Gómìnà Abíọ́dún Oyèbánjí tí gbóríyìn fún iṣẹ̀ akíkanjú Àjọ Elétò Ìdìbò INEC lórí bí wọn ṣe ṣètò ìdìbò gbogboogbò ọdún 2023 yíì ti gbogbo rẹ lọ ní irọwọ àti irọsẹ. Gómìnà Oyèbánjí tẹnu mọ́ àṣeyọrí ẹ̀rọ tuntun,…

Ẹgbẹ́ Òṣèlú APC ló Jáwé Olúborí nínú ipò Ààrẹ ọdún 2023 ní ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́

Akojọpọ èsì ìdìbò gbogboògbò ni Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ fi hàn wí pé, ninu àwọn ẹgbẹ òṣèlú Mejidinlogun ti wọn figagbága láti du ipò Ààrẹ, ẹgbẹ òṣèlú APC ló jáwé Olubori pẹlu ìbò 449,884. Ẹni tíì ṣe Adele Ọgá Àgbà Ile Ẹkọ Fafiti FUNAAB ni ìlú…

Amòfin Sarafadeen Abiodun Allí Jáwé Olúborí Nínú Ìdìbò Ẹkùn Gúsù, Ọ̀yọ́

Amòfin Sarafadeen Abiodun Allí tí ẹgbẹ́ òṣèlú APC ló jáwé olubori ní ẹkùn ìdìbò Gúsù Ọ̀yọ́ gẹgẹ bí o ti farahàn nínú èsì ìdìbò Aṣojú-Ṣòfin tó wáyé ni ọjọ́ Karundinlọgbọn oṣù yìí. Amòfin Alli ti o dije du ipò Aṣoju Ẹkùn Ìdìbò Gúsù Ọ̀yọ́…
button