Take a fresh look at your lifestyle.

Ìjọba Nàìjíríà ti Ṣetán Láti Dín Owó ìṣàkóso ìjọba kù

0 465

Ìjọba Nàìjíríà ti sọ pé òhun  yóò ṣe àtúnyẹ̀wò owó àwọn òṣìṣẹ́ àti  àwọn ilé iṣẹ́ rẹ̀ nípasẹ̀ àti dín owó ìsàkóso ìjọba kù .

Minisita fun eto inawo, eto isuna ati eto ilu, Iyaafin Zainab Ahmed kede eleyi nibi jomitoro ọrọ  lori iwa ibajẹ ati  inawo iṣejọba ni orilẹ-ede Naijiria ti a ṣeto nipasẹ Igbimọ Aṣoju  Ominira (ICPC) ni ilu Abuja.

Iya aafin Ahmed ṣe alaye pé Ààrẹ Muhammadu Buhari ti kan nipa fun  ìgbìmọ ti o nrisi owo oṣù sisan láti mú ìlànà àyẹ̀wò náà wa ṣiṣẹ.

 

Eyitayọ Fauziat Oyetunji

 

Leave a Reply

Your email address will not be published. Required fields are marked *

button