Browsing Category
Ó GBÓNÁ FẸLI-FẸLI
This is a category for LATEST NEWS
Ikọ̀ Super Eagles Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Peregedé Sí Ipele Tó Kángun Sí Àsekágbá Lẹ́yìn Tí Wọ́n Fẹ̀yìn…
Ikọ̀ Super Eagles Orílẹ-èdè Nàìjíríà yayọ̀ aseyege wọn ninu idije Africa Cup of Nations (AFCON) to ń lọ lọwọ nibi ti wọn ti fi àjùlọ wọn han orilẹ-ede Algeria pèlú ayò méjì sí olòdo.(2-0). Wọn si ti peregede sì ipele ẹyọkan to…
Ikọ̀ Super Super Eagles Lu Ikọ̀ Mozambique Ní Àlùbami Pẹ̀lú Ayò Mẹ́rin Sí Òdo(4-0) Peregedé Sì Ipele…
Ikọ̀ Super Eagles borí ìdíje wọn ní papa isere Fes nígbà ti wọn lù alútakò wọn, Mozambique bí ẹní lu aṣọ òfì pẹ̀lú ayò mẹ́rin si òdo(4-0) tí wọ́n sì peregedé sì quarter-finals ìdíje AFCON ọdún 2025.
Ògbóntàrigi agbábọ́ọ̀lù…
Ilé ẹjọ́ tó gajù lọ ní Guinea fìdí àṣeyege ìbò Ààrẹ Doumbouya muĺẹ̀
Ilé ẹjọ́ tó gajù lọ ní Guinea ti fìdí àṣeyege ìbò Ààrẹ Olóyè Mamady Doumbouya muĺẹ̀, pẹ̀lu ìbò ìdá mẹ́rìndín-láàdọ́rùn ún àti díẹ̀.
Eyi jeyọ ninu esi ti wọn kede ni ọsẹ to kọja, lẹyin ibo ọjọ kejidin-lọgbọn ti…
Àwọn ọmọ ológun ti gba àwon ará ìlú tí wón jí gbé ní ìpínlẹ̀ Borno sílẹ̀
Àwọn ọmọ-ogun ti Operation HADIN KAI (OPHK) tún ti ṣe àṣeyọrí pàtàkì mììràn lẹ́nu iṣẹ́ wọn, nígbà tí wọ́n farabalẹ̀ kán lu àwọn oníjàgídíjàgan kan ní ìjọba ìbílẹ̀ Konduga, ti Ìpínlẹ̀ Borno, léèyí tí ó yọrí…
Gómìnà ìpínlẹ̀ Niger ṣèdárò àwọn afaragbà Borgu
Gómìnà ìpínlẹ̀ Niger, Àringbùngbùn Arewa Nàìjíríà, Mohammed Umaru Bago, ti banújẹ́ lórí ìkọlù àwọn oníjàgídíjàgan tí ó ṣẹlẹ̀ láìpẹ́ yìí ní agbègbè ìjọba ìbílẹ̀ Borgu, ti ìpínlẹ̀ náà, tí ó sì ń…
Ẹgbẹ́ ran àwọn tó ye ààrun jẹjerẹ ọyàn bọ́ lọ́wọ́ ni Anambra
Ẹgbẹ́ àwọn obìnrin ìpínlẹ̀ Anambra, ní Amẹ́ríkà Inc. àti Ẹgbẹ́ obìnrin ìpìnlẹ̀ Anambra ti Amẹ́ríkà tí ń rí sí Àjọṣepọ̀ lórí ààrùn jẹjẹrẹ ní Nàìjíríà, ti ṣàkójọ owó tó tó mílíọ́nù náìrà mẹ́ta láti ran…
Peter Obi darapọ̀ mọ́ ADC fún ìdìbò ọdún 2027
Olùdíje fún ipò Ààre ti ẹgbẹ́ Labour ní ọdún 2023, Ọ̀gbẹ́ni Peter Obi, ti darapọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ African Democratic Congress (ADC), ẹgbẹ́ òṣèlú ìṣọ̀kan, fún ìdìbò gbogbogbòò 2027.
Obi kede ifi ẹgbẹ rẹ silẹ ni Ọjọọru, ọjọ…
Gómìnà Aiyedatiwa Ṣàlékún ààbò jákè jádò Ìpínlẹ̀ Ondo
Gómìnà ìpínlè Ondo, Lucky Aiyedatiwa, ti pàse fún àwon elétò ààbò láti túnbọ̀ lékún ìpààrà lórí ààbò jákè kádò àwọn agbègbè àti agbègbè aginjù látàrí ìkọlù Àgọ́ ọlọ́pàá kan ní ìjọba ìbílẹ̀…
Nàìjíríà kí orílẹ̀ èdè Haiti kú oríire àjọ̀dún ọdún méjìlé-lógún- lénígba…
Mínísítà Nàìjíríà fún ọ̀rọ̀ òkèèrè, Aṣojú Yusuf Tuggar, ti kí Mínísítà fún ọ̀rọ̀ òkèèrè orílẹ̀ èdè Haiti, Jean-Victor Harvel Jean-Baptiste, ìjọba àti àwọn ènìyàn Haiti, kú́ oríire àjọ̀dún òmìnira wọn.…
Igbákejì ÀàrẹTanzania pè fún ìfọwọ́sowọ́pọ̀ láti gbógun ti eebi
Igbákejì ÀàrẹTanzania, Philip Mpango ti pé fún ìṣọ̀kan àgbáyé láti kojú ebi àti ìpọ́njú, wípé orílẹ̀ èdè kan kò le dá ogun náà jà.
Gẹgẹ bi alaye kan ti o jade lati ile iṣẹ igbakeji Aarẹ ni ọjọ Ẹti, Mpango pe ipe…