Browsing Category
Ó GBÓNÁ FẸLI-FẸLI
This is a category for LATEST NEWS
Nàìjíríà ṣàfilọ́lẹ̀ ìṣàyẹ̀wò ààrùn jẹjerẹ ọ̀fẹ́ jákèjádò orílẹ̀-èdè
Ìjọba Nàìjíríà ti ṣàfilọ́lẹ̀ ètò ìṣàyẹ̀wò ààrùn jẹjerẹ ọ̀fẹ́ jákèjádò orílẹ̀-èdè,tí yọ́ò ṣètọ́jú ẹgbẹ̀rún mẹ́fà ènìyàn jákèjádò ẹkùn mẹ́fà orílẹ̀-èdè. Ètò yìí wà lára àtúnṣe ìgbìyànjú…
Ààrẹ Tinubu ṣèpàdé pẹ̀lú Adarí Ìṣọ̀kan àwọn orílẹ̀-èdè Adúláwọ̀
Ààrẹ Bola Ahmed Tinubu gbàlejò Adarí Ìṣọ̀kan àwọn orílẹ̀-èdè Adúláwọ̀ (AFRICOM), Ajagun Dagvin Anderson, ní ọjọ́ Aiku ní ilé isẹ́ orílẹ-èdè, Abuja.
Àwọn ti o wà nijokoo nibi ipade naa ni Oludamọran lori ọrọ aabo…
Arábìnrin àkọ́kọ́ Anambra pè fún àyẹ̀wò ààrùn jẹjẹrẹ lásìkò
Ìyàwó Gómìnà ìpínlẹ̀ Anambra, Dókìtà Nonye Soludo ti túnbọ̀ rọ àwọn ènìyàn láti tẹramọ́ ìtọ́jú ìlera wọn, tí ó sì ń kìlọ̀ pé ààrùn jẹjẹrẹ ń gba ẹ̀mí jù, àti wípé àwọn ààrun ìgbà èwe tó ṣeé dènà…
Adarí alátakò South Africa sún sẹ́gbẹ̀ẹ́
Adarí Democratic Alliance (DA), John Steenhuisen ti kéde pé òun kò ní díje ìbò fún ìgbìmọ̀ ẹgbẹ́ lápapọ̀ ní oṣú kẹrin, ìpinnu tó fa ìṣiyèméjì sí ìṣọ̀kan ìjọba àpapọ̀ orílẹ̀-èdè (GNU).
Steenhuisen, to ti ṣadari…
Nàìjíríà, Palestine fìdí àjọṣepọ̀ wọn múl̀ẹ
Mínísítà Nàìjíríà fún ọ̀rọ̀ òkèèrè, Aṣojú Yusuf Tuggar àti Aṣojú orílẹ̀-èdè Palestine sí Nàìjíríà, Muhannad Halmouri, ti gbà láti fì̀dí́ àjọṣepọ̀ ati ìfọwọ́wẹwọ́ aṣojú múl̀ẹ̀ láàrin orílẹ̀-èdè…
Ọ̀fíìsì Ààrẹ Gbósùbà Ràbàndẹ̀ Fún Ìpínlẹ̀ Èkó
Ọ̀fíìsì ààrẹ ti gboriyin fún ipinlẹ Èkó latari pe wọn kéde rẹ̀ pé o jẹ ọkan ninu ipinlẹ to yara dàgbà julọ lagbaye nibi ti imọ ẹrọ to súyọ, wọn jẹri sì pé, ìdàgbàsókè ọtun yìí fihan pé ijọba ààrẹ Tinubu ń ṣe bẹbẹ tẹ̀gàn kọ́.…
Igbákejì Ààrẹ Shettima ṣe àbẹ̀wò sí Gbong Gwom ní Jos Plateau
Igbákejì Ààrẹ Kashim Shettima ti ṣe àbẹ̀wò sí Gbong Gwom ní Jos àti Alága ìgbìmọ̀ àwọn Olóyè tí ó tún jẹ́ Emir ìpínlẹ̀ Plateau, Olóyè, Jacob Gyang Buba.
Igbakeji Aarẹ wa rọ awọn ọmọ Naijiria lati ni ifarada ati iṣọkan…
Nàìjíríà, Turkiye buwọ́lu ìwé àdéhùn MoUs ẹlẹ́ẹ̀kẹsàn án
Adarí Nàìjíríà, Ààrẹ Bola Tinubu pẹ̀lú ẹǹikejì rẹ̀ ti Turkiye, Recep Tayyip Erdogan, ti wà níbi ìbuwọ́lù ìwé àdéhùn ẹlẹ́ẹ̀kẹsàn án tó kó ìdáàbòbò àti ààbò, kárà kátà àti ìdókòwò, iná, àti…
Nàìjíríà–Türkiye tẹ̀síwájú lórí igbiyanju fún ọ̀rọ̀ ìtọ́jú pẹ̀lú iwe àdéhùn
Naijiria ti buwọ́lu ìwé àdéhùn (MoU), lórí ìṣọ̀kan àti ìwà lálàáfíà àwùjọ, tí èyí sì jẹ́ ìbẹ̀rẹ̀ ìgbésẹ̀ pàtàkì ní ṣíṣe ìfilọ́lẹ̀ àti ìgbòòrò ẹ̀ka ìtọ́jú orílẹ̀-èdè.
MoU naa, iwe adehun ẹlẹẹkẹsan…
Ìyàwó Ààrẹ Nàìjíríà Rọ Ọmọ Orílẹ-èdè Yìí Látì Tẹ́wọ́ Gba Ohun Àlùmọ́nì Agbára
Ìyàwó Ààrẹ Orílẹ-èdè yìí ti rọ àwọn ọmọ orílẹ-èdè yìí látì tẹwọ gba ohun alumọni agbara fún àyíká tó mọ́ tótó.
Ó sọ èyí nibi ọrọ rẹ láti sami sì ayeye ọjọ ayika to mọ́ toto agbaye ọdún 2026.
Arabinrin akọkọ rọ gbogbo ọmọ Naijiria…