Browsing Category
ÌRÒYÌN ÈTÒ Ọ̀GÌN ÀTI ÀYÍKÁ
Àgbẹ̀ Ẹlẹ́ja Àrọ̀ Fẹ́ Ìmúlò Ètò Ìṣúná ti Ọdún 2024
Àgbẹ̀ Ẹlẹ́ja Àrọ̀, àjọ Catfish Farmers Association of Nigeria (CAFAN) fẹ́ ìmúlò ètò Ìṣúná ti Ọdún 2024 to múyán lórí fún ìdàgbàsókè ẹ̀ka náà.
Ààrẹ CAFAN, Ogbeni Sunday Onoja pé ipe yi ni ọjọ Ọjọ́bọ̀ ní ìlú Èkó.
Onoja rọ ilé…
Di Dènà Omí Yalé: Ìgbìmọ̀ Ìjọba Ti Ìpínlẹ̀ Gombe Buwọ́lù Mílíọ̀nù Mèjídínlógójì Ó lè Mẹ́sàán Náírà…
Àwọn ìgbìmọ̀ ìjọba ìpínlẹ̀ Gombe(SEC) ti buwọ́lù Mílíọ̀nù Mèjídínlógójì ó le Mẹ́sàán Náírà èyí tí o jẹ́ owó ìrànlọ́wọ́ fún àwọn ènìyàn àti agbègbè tí omí yalé ṣẹlẹ̀ sí.
Kọmísọ́nà fún ètò ìṣúná ni Ìpínlẹ̀ Gombe Malam Mohammed Magaji lo sọ…
Ààrẹ Àjọ CFAN Kìlọ̀ Nípa Pípa Ìgbẹ́ Run Àti Ìlò Ọmọkékeré Láti Se Isẹ́ Alágbàse
Ní ọ̀nà láti ṣètò fún ọdún tó ń bọ̀, ààrẹ àjọ National President, Cocoa Farmers Association of Nigeria (CFAN), Comrade Adeola Adegoke ti korò ojú sí ìgbẹ́ píparun tàbí lílo ọmọdé kékeré fún iṣẹ́ alágbàse nínú oko Kòkó ní…
Ẹgbẹ́ Kan Rọ Ìjọba Láti Se Atìlẹyìn Fún Òkodoro Àgbẹ̀
Ààrẹ àjọ Potato Farmers Association of Nigeria, POFAN, Ọgbẹni, Daniel Okafor, ti rọ ìjọba àpapọ̀ láti se ìrànwọ́ fún Òkodoro àgbẹ̀ ṣugbọn ki wọ́n yẹra fún òfegè àgbẹ̀ olóṣèlú.
O sọ eyi nibi àwẹ̀jẹwẹ̀mu ọlọ́ọdọdún awọn ọmọ ẹgbẹ́…
Àjoyọ̀ Ọdún Kérésìmesì: Oúnjẹ Ṣísòfò A Máa fa Ojú Ọjọ́ Gbígbóná Lágbáyé
Alágbàwí tó ń rí sí ọ̀rọ̀ nípa ojú ọjọ́ àti àyíká fún àjọ Global Initiative for Food Security and Ecosystem Preservation (GIFSEP), Ọgbẹni Michael David,
ti kìlọ pé, ounjẹ ṣísòfò dànù pàápàá jù ní àkókò Kérésìmesì leè fa ojú ọjọ́…
Àwọn Aṣojú Sòfin Ka Àbádòfin Fún Ìdásílẹ̀ Ilé-ìwé Gíga Ètò Ọ̀gbìn
Àwọn aṣojú sòfin ti ka Àbádòfin fún Ìdásílẹ̀ Ilé-ìwé gíga ètò ọ̀gbìn ati ẹ̀kọ́ nípa iṣẹ́ ọwọ́, Ako-Nike, ìpínlè Enugu fún ìgbà èkejì.
Àbádòfin náà ni àfojúsùn láti mú ìmúgbòòrò bá ẹ̀kọ́ ìmọ̀ ẹ̀rọ àti ẹkọ́ nípa iṣẹ́ ọwọ́ ètò…
Akọ́ṣẹ́mọṣẹ́ Nípa Ètò Ọ̀gbìn Gba Àwọn Àgbẹ̀ Níyànjú Láti Gbin Irúgbìn Tí Ó Dára…
Àjọ kan láti ẹka Ìjọba àpapọ tí ó ń rí sí ètò ọ̀gbìn ti gba àwọn àgbẹ̀ níyànjú lati gbin irúgbìn tí ó dára èyí tí yóò jẹ́ ọ̀nà àbáyo sí ìsòro àyípadà ojú ọjọ́
Adelé alága àjọ náà, ọ̀mọ̀wé…
Mímú Ìgbòòrò Bá Ètò Ọrọ̀ Ajé Se Pàtàkì Fún Ìdàgbàsókè Orílẹ̀-èdè- Dapọ Abiọdun
Gómìnà Ìpínlẹ̀ Ogun, Ọmọba Dapọ Abiọdun ti pè fún mímú ìgbòòrò bá ètò ọrọ̀ ajé èyí tí yóò se àmójútó Ètò Ọ̀gbìn, Ìmọ̀ Ẹ̀rọ, Ìdàgbàsókè ohun Àlùmọ́ọ́nì àti bẹ́ẹ̀ bẹ́ẹ̀ lọ
Ó sàlàyé pé…
Ìjọba Ìpínlẹ̀ Ọyọ Ti Se Àgbékalẹ̀ Ètò Èyáwó Láti Se Ìrànlọ́wọ́ Fún Àwọn Àgbẹ̀
Ìjọba Ìpínlẹ̀ Ọyọ ti bẹ̀rẹ̀ pínpín owó tí ó tó bílíọ̀nù kan náírà èyí tí yóò jẹ́ owó ìrànlọ́wọ́ fún àwọn àgbẹ̀ ní àwọn ẹkùn méjèèje tí ó wà ní ìpínlẹ̀ náà
Kọmísọ́nà ètò ọ̀gbìn àti…
Ìjọba Àpapọ̀ Pín Ajílẹ̀ Fún Àwọn Àgbẹ̀ Ọ̀gbìn Àlìkáámọ̀ Ní Ìpínlẹ̀ Bauchi
Ìjọba Àpapọ̀ ti pín ajílẹ̀ àti ohun èlò ọ̀gbìn ẹgbẹ̀rún mẹ́ta fún àwọn àgbẹ̀ ọ̀gbìn àlìkáámọ̀ lójúnà àti mú ìgbòòrò bá ètò ọ̀gbìn ní ìpínlẹ Bauchi
Ìjọba pín àwọn ohun èlò náà léỳíi tí…