Browsing Category
ÌRÒYÌN ÈTÒ Ọ̀GBÌN ÀTI ÀYÍKÁ
Ìjọba ìpínlẹ̀ Kano Kéde Ìfura Lórí Àìsàn Tó Ń Ja Ẹyẹ Abìyẹ́
Ìjọba ìpínlẹ̀ Kano ti kéde Ìfura fáráyé lórí àìsàn-Avian Influenza (AI) tó ń ja Ẹyẹ abìyẹ́ tó bẹ́ sílẹ̀ ní agbègbè ìjọba ìbílẹ̀ Gwale ìpínlẹ̀ náà.
Kọmísọ́nà fún ètò ọ̀gbìn àti ohun àlùmọ́nì, Dókítà Danjuma Mahmoud ló sọ èyí…
Ìrọ̀rùn Dé, Ọ̀wọ́ngógó Oúnjẹ Yóò Dẹ̀rọ̀: Àwọn Alẹ́nulọ́rọ̀ Fọwọ́sowọ́pọ̀ Pẹ̀lú Ìjọba…
Lójúnà àti mú kí oúnjẹ pọ̀ yanturu ní Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, àwọn ilé iṣẹ́ kan ti dìde ìrànlọ́wọ́ fún ìjọba àpapọ̀ láti jẹ́ kí ìlérí náà wá sí ìmúsẹ nígbà tí wọ́n jẹ́jẹ̀ẹ́ láti se ìrànlọ́wọ́ fún àwọn…
Gómìnà Ìpínlẹ̀ Kebbi San Owó Fún Àwọn Ti Yòó Ṣe Àtúnṣe Àwọn Pópónà Ìgbèríko.
Gómìnà Ìpínlẹ̀ Kebbi ti san Mílíọ̀nù Mẹta ole ni àádọta Náírà fún àwọn òṣìṣẹ́ (RAAMP) ti yóò ṣe àwọn pópónà ìgbèríko.
Alhaji Shehu Mu'azu tó jẹ Kọmísọ́nà fún ètò ògbìn àti iṣé ìgbèríko lo sọ èyí di mímọ ní ọjọ́ ajé ni kebbi nígbàtí o n…
Ìjọba Ní Láti Fi Kún Ìpèsè Ohun Èèlò Gbogbo Fún Agbẹ̀- Akọ́sẹ́mọsẹ́
Àgbẹ̀ akọ́sẹ́mọsẹ́, ọgbẹni Titilayo Adebanjo ti rọ ìjọba ìpínlẹ̀ àti apapọ̀ lati fi kun oye isuna ọdọọdún àgbẹ láti jẹ ki ounjẹ sunwa bọ̀ ni Nàìjíríà.
Adebanjo, to jẹ oga ile iṣẹ Agrorebirth ló gba ijọba niyanju yìí nigbati o n…
Ilé -Iṣẹ́ Tí Ó Wà Ní Títìpa Látàrí Bíba Afẹ́fẹ́ Jẹ́ Ní Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ Ti Bẹ̀rẹ̀ Iṣẹ́…
Ìjọba ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ ti sí ilé isẹ́ tí ó ń lo táyà gẹ́gẹ́ bí ohun èlò ní ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́, èyí tí ó ti wà ní títìpa tẹ́lẹ̀rí látàrí bíba afẹ́fẹ́ jẹ́ àti kíkó ìnira bá àwùjọ
Kọmísọ́nà fún…
Ìjọba Ìpínlẹ̀ Enugu: ìṣòwò Ọgbà Oko Ń lá Ni A Ń Ṣe O, Ki Ṣe Owó Màálù.
Ìjọba Ìpínlẹ̀ Enugu sọ wí pé àwọn kò ṣe owó RUGA èyí tí o nise pẹ̀lú owó Maalu, bikòṣe owó Ranch èyí tó nisè pẹ̀lú ọgbà àjàrà nlá ti àwọn ènìyàn yóò fi gbin nkán ọgbin sí ati ṣinṣin nkan osin
Nínú atẹjade kan láti ọwọ́ Kọmísọ́nà fún…
Ilé Ìfowópamọ́ Ti Mùsùlùmí Ti Fi Ìgbáradì Rẹ̀ Léde Láti Se Ìrànlọ́wọ́ Fún…
Ilé ìfowópamọ́ tí ó jẹ́ tí àwọn ẹlẹ́sìn Mùsùlùmí ti fi ìgbáradì rẹ̀ léde láti se àtìlẹyìn fún Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà fún ìdàgbàsókè tí ó péye
Adarí ilé ìfowópamọ́ náà, Ọ̀gbẹ́ni Javed…
Àjọ AFAN: Ìpínlẹ̀ Enugu Yóò Gbádùn Ìpèsè Ẹ̀gẹ́ Yanturu
Alága àjọ , All Farmers Association of Nigeria (AFAN) ni ìpínlẹ̀ Enugu, ọ̀gbẹ́ni Romanus Eze, ti sọ pé ìrètí wà fún ìpèsè ẹ̀gẹ́ yanturu ninu ọdún yìí.
Ọgbẹni Eze sọ eyi níbi ìfòròwánilẹ́nuwò ni ilu Enugu ni ọjọ Ọjọ́rú. O sọ pe ọpọ…
Ìjọba Àpapọ̀ Àti Ìpínlẹ Kebbi Ti Parí Ètò Láti Mú Ìgbòòrò Bá Ètò Ọ̀gbìn Èyí Tí…
Ìjọba àpapọ̀ àti Ìpínlẹ̀ Kebbi ti gbé ìgbésẹ̀ akin láti mú ìgbòòrò bá ètò ọ̀gbìn èyí tí yóò mú àdíkù bà ọ̀wọ́ngógó oúnjẹ, tí oúnjẹ yóò sì wà lọ́pọ̀ yanturu
Mínísítà Fún Ètò Ọ̀gbìn àti…
Ìsẹ̀lẹ̀ Idagiri Ẹgbẹ̀rún Kan-lé-lẹ́ẹ̀dẹ́ẹ́gbẹ̀ta Ní Ó Wáyé Ní Ìpínlẹ̀ Eko Nínú Ọdún…
Àjọ tí ó ń mójútó ìsẹ̀lẹ̀ pàjáwìrì ní ìpínlẹ̀ Eko, (LASEMA) ti sọ pé, ó tó ìsẹ̀lẹ̀ ẹgbẹ̀rún kan lé lẹ́ẹ̀dẹ́ẹ́gbẹ̀ta tí ó wáyé láàrin ọjọ́ kíní osù kíní ọdún 2023 sí ọjọ́ kọkànlélọ́gbọ̀n osù kejìlá…