Take a fresh look at your lifestyle.

Àjọ Ọmọ Ogun Sọ Ìmọ̀ Àwọn Agbésùmọ̀mí Di Òtúbáńtẹ́ Ní Òpópónà Kaduna

Àjọ Ọmọ Ogun ti ìpín alákọ̀kọ́ọ́ ní Ìlú Kaduna ti se àwọn agbésùmọ̀mí báṣu-bàṣu, tí ọgbọ̀n ènìyàn sì gba òmìnira kúrò lọ́wọ́ àwọn esinsin-ò-kọkú náà. Ikọ̀ Ọmọ Ogun gba Alùpùpù méjì lọ́wọ́ọ wọn, Ó sì sọ…

Àjọ Alámòjútóó Ìsẹ̀lẹ̀ Pàjáwìrì Dóòlà Ẹ̀mí Àwọn Ènìyàn Níbi Ilé Tí Ó Dà Wó…

Kò dín ní ènìyàn mẹ́rìndínlọ́gbọ̀n tí àjọ tí ó ń mójú tó ìsẹ̀lẹ̀ pàjáwìrì àti àwọn tí ọ̀rọ̀ kàn dóòlà ẹ̀mí wọn nínú ìjàm̀bá Ilé tí ó dàwó lulẹ̀ ní Gwarimpa, Ìlú Abuja, olú Ìlú Nàìjíríà.…

Tinubu Sàdéhùn Mímú Ìgbòòrò Bá Ètò Ọ̀gbìn Àti Ìwakùsà Ní Ìpínlẹ̀ Zamfara

Olùdíje sí ipò ààrẹ lábẹ́ òsèlú olóṣùṣù ọwọ̀ (APC) Asiwaju Bọla Tinubu se àdéhùn ní ọjọ́ Àìkú (Sunday) wípé òun yóò mú ìgbòòrò bá ètò ọ̀gbín àti ìwakùsà lójúnà àti mú ìdàgbàsókè bá ọrọ̀ ajé…
button