Take a fresh look at your lifestyle.

Ààrẹ Tí Wọ́n Ṣẹ̀ṣẹ̀ Dìbò Yàn Gba Àwọn Ẹlẹ́sìn Ìsìláàmù Ní Iyànjú

Ààrẹ Nàìjíríà tí wọn ṣẹṣẹ dìbò yàn ti gba  àwọn Mùsùlùmí Orílẹ̀-èdè yìí ní Iyànjú ní àkókò ààwẹ̀ Ramadan pé kí wọ́n fi ìwà jọ Prophet Muhammad nínú ìrẹ̀lẹ̀, ìdáríjì, àti iṣẹ́ ìsìn wọn sí ọmọ enìkejì wọn. Tinúbú gba àwọn…

Àwọn Adìhámọ́ra Ogun Pa Ènìyàn Mẹ́rìnlá Nínú Ìkọ̀lù Sí Orílẹ̀-èdè Burkina Faso

Àwọn Adìhámọ́ra Ogun ti pa ènìyàn Mẹ́rìnlá ní itòsí ilu Kaya tó wà ni agbègbè Àríwá. Ológun mẹ́rin sì wà lára àwọn ènìyàn tí wọ́n pa. Ìròyìn ròó pé ìkọ̀lù náà se pẹki n pẹ̀kí ń pẹ̀kí pẹ̀lú àbẹ̀wò tí adarí ìjọba fìdíhẹ́, Captain Ibrahim…

Òṣèré Ìhìnrere Tó Fi Ìlú Òyìnbó Se Ibùjókòó Ṣetán Láti Gbé Àwo Eré Tuntun Jáde

Òṣèré, Vincent Efetobo tó fi ìlù ọba se Ibùjókòó ti ṣetán láti gbé àwo eré tuntun tó pe àkọ́lé rẹ̀ ní"Ọmọ Obìnrin kékeré jòjoòló" jáde. Ó ní lọ́kàn láti di òṣèré nígbà tí ó ń dàgbà ní orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ṣùgbọn ìwé tí ó lọ ká ní ìlú ọba…
button