Take a fresh look at your lifestyle.

Èmi Yóò Gbé Ìjọba Sílẹ̀ Lọ́dún Tó Ń bọ̀ – Ààrẹ Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Ṣé Ìdánilójú Fún Àwọn Àrà Ìlú

Ààrẹ Muhammadu Buhari ní ọjọ́ Ajé tún ṣé àdéhùn rẹ̀ láti gbé ìjọba lé ẹní tí wọ́n bá fí ibo Yan gẹ́gẹ́ bí ààrẹ lọ́wọ́ ní ọjọ́ kọkàndínlọ́gbọ̀n oṣù karùn-ún ọdún tó ń bọ̀, ó sọ pé àsìkò rẹ̀ yóò dópin lọ́jọ́ yẹn ní ìbámu pẹ̀lú àwọn ìlànà…

Ẹsùn Apọju Ìgbá Lé Mẹ́fà Bílíọ̀nù Náírà (206bn) Nínú Ètò Ìṣúná 2023, Mínísítà Jẹ́wọ́

Mínísítà fún ètò ìnáwó, Zainab Ahmed tí gbà wípé àṣìṣe kàn wà nínú ètò ìṣúná tí ilé-iṣẹ́ tó ń rí sí ètò ọmọnìyàn bí ìgbá lé nfa bílíọ̀nù Náírà (206 billion naira) tí wọ́n bá nínú àbá ètò ìṣúná tí ilé-iṣẹ́ náà jẹ́ àṣìṣe nípasẹ̀ ilé-iṣẹ́ ètò…

Ààrẹ Buhari Fí Àbá-dòfin Ètò Idokoowo Àwùjọ Ṣòwò Sí Ilé-ìgbìmọ̀ Aṣòfin Àgbà

Ààrẹ Muhammadu Buhari tí kọ̀wé sí Ilé-ìgbìmọ̀ Aṣòfin Àgbà látí fí òfin sí Ètò Idoko-òwò Àwùjọ (National Social Investment Programme NSIP) ní Nàìjíríà. Èyí jẹ́ ọ̀kan nínú àwọn ìbéèrè tí a fí ránṣẹ sí ilé-ìgbìmọ̀ aṣòfin àgbà ní ọjọ́…

Ìpínlẹ̀ Ebonyi: Alága Ẹgbẹ́ Òṣèlú APC Bú Ẹnu Àtẹ Lú Iná Tó Ṣẹlẹ̀ Ní Ọ́fíìsì Àjọ INEC

Alága ẹgbẹ́ òṣèlú APC ní ìpínlẹ̀ Ebonyi, Ọgbẹni Stanley Okoro Emegha tí bú ẹnu àtẹ lú dídá'ná sún ilé-iṣẹ́ élétó ìdìbò (Independent National Electoral Commission INEC) tó wà ní Izzi, ìjọba ìbílẹ̀ Iboko, ní ìpínlẹ̀ Ebonyi. Okoro Emegha…
button