Take a fresh look at your lifestyle.

Nàìjíríà Yòó Ṣé Àtilẹ́yìn Ìbáṣépọ̀ Àgbáyé Fún Ètò Ẹ̀kọ́

Mìnísítà Ìpínlẹ̀ fún ètò Ẹ̀kọ́, Dókítà Yusuf Sununu, sọ pé Ìjọba tí ṣétan láti ṣé àtilẹ́yìn Ajọṣépọ̀ Àgbáyé Fún Ẹ̀kọ́, GPE, látí ṣé àṣéyọrí ìdágbàsóké ní ẹ̀ká nàá. Sununu sọ èyí ní ilé-iṣẹ́ rẹ̀ ní Abuja Nígbà tó padé pẹ̀lú àwọn òṣíṣẹ́…

Ìpínlẹ̀ Èkó Kìlọ Fún Àwọn Òntájà Lóju Òpópó-ọnà Ojú-Ìrìn Láti Kúró Pátápátá

Ìjọba Ìpínlẹ̀ Èkó, Ìwọ̀ òòrun guusù orílẹ̀-èdè Náìjíríà, ní ọjọ́ Áìkú, fún àwọn olúgbé àti ontájà òpópónà ojú-ìrìn Èkó sí Badagry wọ́nyí ní ọjọ́ méje láti kúró pátápátá tábi páda sẹ́yìn. Òpópónà Lagos-Badagry naa ni ojuna ọkọ oju-irin…

Ìgbákéji Agbẹ́núsọ Àwọn Aṣóju Ṣofìn Gbá Ìjọba Níyànjú Láti Ṣé Réré Lóri Àléfàá

Ìgbákéji agbẹ́núsọ tí Ilé-ìgbìmọ́ Aṣóju ṣofìn tí Naijiria, Benjamin Kalu sọ pé Ìlé-ìgbìmọ́ àṣofìn gbọ́dọ̀ ríi dájú pé gbogbo àwọn ìlànà ofiìn àtí àbádofìn rẹ̀ ṣé déédé ọná abàyọ́ áìní àwọn ọmọ Orílẹ̀-èdè Naijiria nípasẹ ìṣákósó tó dará.…

Àtìlẹ́yìn Fún Àwọn Ìpínlẹ̀ Kàn Nàìjíríà Lórí Ètò MSMEs

Lójúnà látí rán àkitiyan àwọn Ìjọba Nàìjíríà látí mú ìlọsíwájú bá ètò-ọ̀rọ̀ àjé àti ṣé ìdásílẹ̀ ìpèsè iṣẹ́, ẹgbẹ́ àwọn alabaṣepọ kàn lórí ètò àwọn ilé iṣẹ́ kerejekereje kàn, tí gbèrò ànfààní fún àwọn mílíọ̀nù kán lé díẹ̀ àwọn ènìyàn ní…
button