Ilé-iṣẹ́ Ajílè ọ̀gbìn Dangote ṣe Ìgbéláruge Ìdàgbàsókè iṣẹ́-ọ̀gbìn – Ẹgbẹ́
Eyitayọ Fauziat Oyetunji
Ilé-iṣẹ́ ajílè Dangote,gẹ́gẹ́ bí nǹkan tí Ọ̀gbẹ́ni Olúṣọlá Obadimú, Olùdarí Gbogbogboò Ẹgbẹ́ Aṣojú Àwọn Ilé-iṣẹ́ Ìṣòwò, Ilé-iṣẹ́ tó ń ṣẹ̀dá,àlùmọ́nì inú ilẹ̀, àti iṣẹ́-ọ̀gbìn (NACCIMA), yóò ṣe ìgbéláruge ìdàgbàsókè iṣẹ́ ọ̀gbìn orílẹ̀-èdè.
Ọga NACCIMA sọ eyi ni ọjọ Abamẹta ni Ilu Eko nigba to n jabọ lori abẹwo si ile-iṣẹ Ajile Dangote ni agbegbe Ibẹju Lekki.
O sọ pe ipilẹṣẹ naa yoo ṣe ipese aabo ounjẹ ati pe yoo ṣe agbekalẹ ọpọlọpọ ipese iṣẹ fun awọn ọmọ orilẹ-ede Naijiria ati awọn ọmọ Afirika miiran.
Leave a Reply