Ààrẹ Muhammadu Buhari késí àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà láti jẹ́kí ànfàní orílẹ̀-èdè kó jẹwọ́n lógún, kósì lékè àwọn ìwà ìmọtara-ẹni-nìkan.
Nínú ọ̀rọ̀ Eid-el Kabir rẹẹ̀ sí àwọn Mùsùlùmí orílẹ̀-èdè Nàìjíríà àti àwọn ará ìlú mìíràn, Ààrẹ Buhari sọ pé “tí a bá ń wu àwọn ẹ̀kọ́ tí àwọn ẹ̀sìn wa ń kọ́wa níwà, ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn ibi tí ó ń sẹlẹ̀ ní àwùjọ wa ni à báá ti yanjú.”
Ọláyinká Akíntọ́lá.
Leave a Reply