Take a fresh look at your lifestyle.

Kòsógun kòsíjà lórí Ààlà Kamẹrúùn àti Nàìjíríà

Eyitayọ Fauziat Oyetunji

0 240

Ìjọba orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ti ṣàlàyé pé ìṣẹ̀lẹ̀  tó wáyé láìpẹ́ yìí kìí ṣe ogun bẹ́ẹ̀ni kìí sìí ṣe ìjà.

Oludari Agba fun igbimọ aala lorilẹ-ede lapapọ, Awọnlẹ Adamu Adaji,ṣalaye  ni Abuja nibi  apero kan lori awọn igbesẹ ti Igbimọ naa gbe laipẹ.

O sọ pe iroyin ti awọn ile-iroyin kan fi sita nipa bo ṣe n lọ laarin awọn ologun aabo orilẹ-ede Kamẹruun ati awọn ọmọ abinibi  agbegbe Kwaja ati ilẹ-oko wọn ko ri bẹẹ rara,Awọnlẹ Adaji sọ pe,ko si nkan to jọ ija tabi ogun laarin wọn ti awọn orilẹ-ede mejeeji si jẹ aladugbo pelu ibaṣepọ to danmọran.

Leave a Reply

Your email address will not be published. Required fields are marked *

button