Take a fresh look at your lifestyle.
Browsing Tag

Prof. Yẹmi Osinbajo

Kò Sí Orílẹ̀-èdè Tí o Leè Lékè Nípa Ìwà Àìní Òdodo Àti Ẹ̀sẹ̀ – Ìgbákejì Ààrẹ Yemi Osinbajo

Ìsìn Ìbúra sípò Ààrẹ Àti Igbákejì Ààrẹ Orílẹ̀-èdè Nàíjíríà ọdun 2023 wáyé ní ilé Ìjọsìn ni ecumenical Centre nílùú Abuja ní ọjọ́ kejidinlọgbọn, oṣù karùn-ún, ọdun 2023 Àwọn ènìyàn pàtàkì  lo wa ni bi ìsìn yii, Lára àwọn ènìyàn pàtàkì tí ó…

Ìgbákejì Ààrẹ Orílẹ̀-èdè Yìí Rọ́ Àwọn Àdári Ilé-ẹ̀kọ́ Gíga Nàìjíríà Látí Ṣé Ìpolongo Ilé-ìwé Wọ́n

Ìgbákejì Ààrẹ Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, Ọ̀jọ̀gbọ́n Yemi Osinbajo tí rọ́ àwọn ilé-ẹ̀kọ́ gíga ní Nàìjíríà látí ṣiṣẹ́ takuntakun fún ìgbéga àtí ọnà àtí máà gbá owó wọlé fún àwọn ilé-ẹ̀kọ́ wọnyí nítori wípé kò sí Orílẹ̀-èdè kàn lágbayé tó lé ṣé ètò…
button