Kò Sí Orílẹ̀-èdè Tí o Leè Lékè Nípa Ìwà Àìní Òdodo Àti Ẹ̀sẹ̀ – Ìgbákejì Ààrẹ Yemi Osinbajo
Ìsìn Ìbúra sípò Ààrẹ Àti Igbákejì Ààrẹ Orílẹ̀-èdè Nàíjíríà ọdun 2023 wáyé ní ilé Ìjọsìn ni ecumenical Centre nílùú Abuja ní ọjọ́ kejidinlọgbọn, oṣù karùn-ún, ọdun 2023
Àwọn ènìyàn pàtàkì lo wa ni bi ìsìn yii, Lára àwọn ènìyàn pàtàkì tí ó…