Gómìnà nígbà kàn rí ní ìpínlẹ̀ Ekiti, Ayodele Fayose tí gbóríyìn fún àwọn ìgbésẹ̀ ìgboyà tí Ààrẹ Bola Tinubu ń gbé báyìí.
Nitorinà, Ó ń kési gbogbo ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà látí ṣé àtìlẹ́yìn fún Ààrẹ, nítori wípé “kó lé dá ṣé.”
Fayose ṣé ìmọràn náà ní ìlú Abuja ní Ọjọ́bọ̀ làkókò tó n bá àwọn òníròyìn Ilé-iṣẹ́ Ààrẹ sọrọ, lẹyìn tó ṣé àbẹwò ìṣọ̀kan sí Olori Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà náà.
Leave a Reply