Browsing Category
ÌRÒYÌN ÌDÁRAYÀ
This is a category for sport news
Olùkọ́ni Sami Trabelsi Fí Tunisia Sílẹ̀ Lẹ́yìn Tó Pàdánù Nínú Ìdíje AFCON
Olùkọ́ni àgbà Tunisia Sami Trabelsi tí fí ipò rẹ̀ sílẹ̀ lẹ́yìn tí wọ́n yọ ẹgbẹ́ náà kúrò nínú ìdíje African Cup of Nations ní ìpele Round of 16, gẹ́gẹ́ bí àjọ bọ́ọ̀lù orílẹ̀-èdè náà ṣe fìdí rẹ̀ múlẹ̀.
Nínú ìròyìn kan lórí facebook, àjọ…
Agbábọ́ọ̀lù Gueye Jẹ́ kí Ikọ̀ Senegal Wọ Ipele Kẹta Tó Kángun Sí Àsekágbá Ìdíje AFCON
Ògbóntàrigi agbábọ́ọ̀lù ní ipò àárín fún ikọ̀ Senegal, Pape Gueye sọ bọ́ọ̀lù ní igbà méjì sínú àwọ̀n nígbà ti ikọ̀ Senegal jà raburabu látẹ̀yìn wá láti lu ikọ̀ Sudan ní ayò mẹ́ta sí oókan(3-1) ní ìpele kẹta tó kángun sí àsekágbá ìdíje…
’Super Eagles’ Bẹ̀rẹ̀ Ìgbaradì Fún Ìpele Oníkọ̀ Mẹ́rìndínlógún Tí AFCON 2025
Bí Super Eagles ṣe ń múra sílẹ̀ fún ifẹsẹwọnsẹ wọn nínú ìdíje bọ́ọ̀lù Adúláwọ̀ "African Cup of Nations" (AFCON) ní ìpele oníkọ̀ mẹ́rìndínlógún pẹ̀lú Mozambique ní ọjọ́ karùn-ún oṣù kìíní, ọdún 2026, àwọn òun márùn-ún wọ̀nyí ló ń ṣẹlẹ̀ sí…
FIFA Ṣàfihàn Orúkọ Àwọn Ọmọ Nàìjíríà Tí Yóò Jẹ́ Olùdarí Eré Ìdárayá ti 2026
FIFA ti ṣe àkójọpọ̀ Orúkọ Àwọn Ọmọ Nàìjíríà tí yóò jẹ́ Olùdarí eré ìdárayá ní Àgbáyé ti ọdún 2026 ní gbángba, ó sì jẹ́rìí sí i pé àwọn ọgbọ̀n (30) ní a fọwọ́ sí láti dárí àwọn ìdíje àgbáyé ní onírúurú ẹ̀ka.
Àkójọpọ̀ ọdọọdún náà ní…
Lookman, Chelle Wà Lára Agbábọ́ọ̀lù Mọkànlá Tó Yarantí Jùlọ Tí Wọ́n Dárúkọ Ní Ìdíje AFCON Ọdún 2025…
Agbábọ́ọ̀lù ará ipò iwájú Super Eagles orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, Lookman àti akọ́nimọ̀ọ́gbá, Eric Chelle ní wọ́n ti kéde pé wọ́n wà lára agbábọ́ọ̀lù mọkànlá tó yarantí jùlọ ní ìpele àkọkọ tí Idije Africa Cup of Nations (AFCON), Ọdun…
Ìpínlẹ̀ Ogun Yóò Fi Ẹwà Àṣà, Ìrìnajò-afẹ́ Rẹ Hàn Látàrí Àjọ̀dún Ìdíje Eré Ìdárayá
Ìpínlẹ̀ Ogun ti sọ pé àwọn yóò fi ẹwà Àṣà, Ìrìnajo-afẹ́ wọn hàn fáráyé látàrí àjọ̀dun Ìdíje eré ìdárayá Ẹlẹ́ẹ̀kejìlélógún National Sports Festival (NSF), tí wọ́n pè ní "Gateway Games" to ń lọ lọ́wọ́ ní ìlú Abeokuta.
Ọ̀gbẹ́ni Dare…
Wọ́n Fi Ìbò Gbé Ààrẹ NFF Wọlé Gẹgẹ Bí Ààrẹ WAFU B
Alága àjọ Nigeria Premier Football League (NPFL), Otunba Gbenga Elegbeleye ti gbósùbà fún idibo ààrẹ àjọ Nigeria Football Federation (NFF) Alhaji Ibrahim Gusau sì ipò alàkóso CAF West Africa Football Union(WAFU) B. bi èyí to dára àti…
Ààrẹ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà kéde Ìbẹ̀rẹ̀ Àjọ̀dún Eré Ìdárayá Orílẹ̀-èdè
Tí ìdùnnú tí ayọ̀ ní gbogbo àwọn ènìyàn wà nílùú Abeokuta, tó jẹ́ olu-ilu ìpínlẹ̀ Ogun, nígbà tí Ààrẹ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ṣe kéde ayẹyẹ eré ìdárayá ẹlẹ́ẹ̀kejìlélógún ní ìforígbárí, pẹ̀lú àwọn olóyè, àwọn olóṣèlú, àwọn ògbóǹtagí eré ìdárayá…
Ààrẹ Nàìjíríà Ṣàtúnṣe Ìgbìmọ̀ Eré Ìdárayá Orílẹ̀-èdè Fún Ìlọsíwájú
Ààrẹ Bola Tinubu kéde àtúnṣe tí Ìgbìmọ̀ Eré Ìdárayá tí Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà (National Sports Commission NSC) tó tí wá fún ìgbà pípẹ́ láti dáàbòbo ìṣàkóso eré ìdárayá kúrò lọ́wọ́ àwọn ìdádúró ìjọba àti àwọn ìdíwọ́ mìíràn.
Ààrẹ ló sọ…
Taiwo Awoniyi Àgbábọ́ọ̀lù Ọmọ Nàìjíríà Jí Pàdà Lẹ́yìn Iṣẹ́ Abẹ́
Àgbábọ́ọ̀lù 'Super Eagles' tí Nàìjíríà àti Nottingham Forest tí Orílẹ̀-èdè England, Taiwo Awoniyi, tí jí pàdà lẹ́yìn tó tí ṣiṣẹ́ abẹ́ lẹ́yìn ìpalára ikùn nlá kán tó ní lórí pápá.
Ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà náà fí ikùn kọlù ìgi golí ní…