Browsing Category
ÌRÒYÌN ÒSÈLÚ
This is a category for politics news
Ààrẹ Tinubu Rọ̀ Àwọn Ènìyàn Láti Dibò Alalafia Ní FCT, Kano, Àti Ipinlẹ Rivers
Ààrẹ Bola Ahmed Tinubu ti rọ àwọn olùdìbò tó yẹ ní Federal Capital Territory (FCT), Kano àti Rivers láti kópa nínú ìdìbò ní ọjọ́ Àbámẹ́ta láìsí ìbẹ̀rù, ó ń ké sí àwọn òṣèlú láti yẹra fún ìwà ipá àti ìwà ìgbónára.
Nínú ìkéde kan…
Ààrẹ Tinubu Yan Gómìnà ìpínlẹ̀ Gombe Gẹ́gẹ́ Bí Aṣojú Ìrètí Tuntun Àti Akọ̀wé
Ààrẹ Bola Tinubu ti yan Gómìnà Ìpínlẹ̀ Gombe, Muhammadu Yahaya, gẹ́gẹ́ bí Aṣojú Ìrètí Tuntun àti Akọ̀wẹ́ fún Ìrànlọ́wọ́ Ẹgbẹ́, Ìbáṣepọ̀ àti Ìṣíṣẹ́.
Ìyàn náà wà nínú lẹ́tà kan tí Ààrẹ fọwọ́ sí, tí ó pàṣẹ fún Gómìnà Yahaya láti gba àwọn…
Ẹgbẹ́ Òṣèlú APC Ti Ìpínlẹ̀ Kano Wà Lẹ́yìn Ààrẹ Tinubu, Gómìnà Yusuf Fún Ìdìbò Ọdún 2027
Àwọn alenulọ́rọ̀ ẹgbẹ́ All Progressives Congress (APC) tí agbègbè Ariwa ìgbìmọ̀ aṣòfin ti ìlú Kano ti ṣe ìlérí láti kó ìtìlẹ́yìn ńlá fún Ààrẹ Bola Tinubu, Gómìnà Abba Yusuf àti Igbákejì Ààrẹ ti Ìgbìmọ̀ aṣòfin, Barau Jibrin, jọ…
Ẹgbẹ́ Òṣèlú APC Osun Gba Àwọn Tó Sákúrò Ní Ègbé Òṣèlú PDP Mọ́ra, Fi Òùntẹ̀ Lu Ààrẹ Tinubu
Ẹgbẹ́ oṣelu All Progressives Congress (APC) ní Ìpínlẹ̀ Osun ti gbà àwọn ọmọ ẹgbẹ́ ilé igbimo aṣòfin ti Peoples Democratic Party (PDP) wọlé sí ẹgbẹ oṣelu APC ní ìpínlẹ̀ náà.
Nígbà tí ó ń sọ̀rọ̀ níbi àsè ní Osogbo, ní ọjọ́…
Àjọ INEC, NPC Gbìmọ̀ Pọ̀ Fún Ìdìbò Àlàáfíà Ìlú FCT, Abuja
Àjọ (INEC) àti àjọ (NPC) ti ṣe agbekalẹ ajọṣepọ ilana kan lati teramọ́ aabo idibo ati igbega iwa alaafia ṣaaju idibo Igbimọ agbegbe Federal Capital Territory (FCT) to ń bọ̀.
Ifowosowopo isọdọtun naa ni a fi idi rẹ̀ mulẹ̀…
Òsìsẹ́ Elétò Ìdìbò Ló Fa Èrò Tó Kéré Láti Dìbò – Alága Ẹgbẹ́ Òṣèlú APC
Alaga àpapọ ẹgbẹ oṣelu All Progressives Congress (APC), Ọjọgbọn Nentawe Yilwatda ti sọ pé Osise ètò ìdìbò to pọ̀ wà lára okunfa oludibo to kéré jọjọ.
Èyí jẹyọ bakanna lati odò oludamọran pataki sì alaga apapo egbé oselu APC…
A Kò Ní Jẹ́ Kí Ẹnikẹ́ni Tẹ Ẹgbẹ́ Òṣèlú PDP Mọ́lẹ̀ Mọ́ – Makinde Kéde
Gómìnà Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́, Seyi Makinde ti kéde wí pé òun kò ní fi ààyè sílẹ̀ kí ẹnikẹ́ni tẹ ẹgbẹ́ òṣèlú PDP (People's Democratic Party) mọ́lẹ̀, fun ẹgbẹ́ míràn láti wà lórí ipò àṣẹ.
Makinde ló sọ ọ̀rọ̀ yìí di mímọ̀ lásìkò tó n ṣí ilé ẹgbẹ́…
PDP Gbé Ìgbésẹ̀ Láti Parí Ikùn Sínú Láàrín Àwọn Ọmọ Ẹgbẹ́
Ẹgbẹ́ Òṣèlú 'Peoples Democratic Party PDP' tí bẹ̀rẹ̀ ìgbésẹ̀ láti yanjú àwọn ikùn sínú láàrin àwọn ọmọ ẹgbẹ́, bí Ìgbìmọ̀ Àwọn Olóòtú (BoT) àti Ìgbìmọ̀ Àwọn Iṣẹ́ tí ẹgbẹ́ náà ṣe ń ṣé ìdánilójú ìṣọ̀kan, láti bọ̀wọ̀ fún àwọn ìdájọ́ ilé-ẹjọ́…
Masari Ṣe Ìfilọ́lẹ̀ Àwọn Olùṣàkóso Ìrètí Tuntun Ní Katsina
Olùṣàkóso Àríwá-Ìwọ̀-Oòrùn ti ètò Ààrẹ Bola Tinubu Ìrètí Tuntun (Renew Hope), Alhaji Aminu Masari ti ṣe ìfilọ́lẹ̀ Àwọn Olùṣàkóso Ìrètí Tuntun ní Àwọn Agbègbè Ìjọba Ìbílẹ̀ mẹ́rinlèlọ́gbọ̀n (34) ní Ìpínlẹ̀ Katsina.
Ìfilọ́lẹ̀ náà wáyé…
Ilé Aṣòfin Èkó Sẹ́ awuyewuye Ìròyìn Kan Pé, Wọ́n Fẹ́ Ra Ilé Ní Abuja Àti Ọkọ̀ Olówó Iyebíye.
Ilé Ìgbìmọ̀ Aṣòfin Ìpínlẹ̀ Èkó ti ṣẹ́ awuyewuye ìròyìn kan pé, àwọn fẹ́ ra ilé fúnra àwọn ní ìlú Abuja àti ọkọ̀ olówó iyebíye.
Nínú ìpàdé ìjíròrò Ilé Aṣòfin náà lọ́jọ́ Bọ (Thursday) ní wọ́n ti bẹnu àtẹ́ lu ìròyìn tó ń fò…