Take a fresh look at your lifestyle.

Ìròyìn Ayọ̀: Àrùn Ebola Di Ohun Àfìsẹ́yìn Tí Egúngún Ń Fi Asọ Ní Orílẹ̀-èdè Uganda-…

Ènìyàn mẹ́jọ tí àyẹ̀wò fi hàn pé àrùn Ebola ń yọ lẹ́nu nígbà tí àrùn náà  súyọ ní ọ̀ṣẹ̀ tí ó kọjá ní ó ti wà ní ipò àlàáfíà, tí wọn si ti kúrò ní ilé ìwòsàn   Àjọ WHO gbósùbà fún ìjọba…

Àdánù Ńlá Ni Ikú Edwin Clark Jẹ́ Fún Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà- Igbákejì Ààrẹ Shettima

Igbákejì Ààrẹ Kashim Shettima ti fi àìdùnnú ọkàn hàn látàrí ìpapòdà olóyè Edwin Clark, ó sàpèjúwe ikú rẹ gẹ́gẹ́ bi àdánù ńlá fún Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà   Nínú ọ̀rọ̀ ìbánikẹ́dùn rẹ̀, ó…

Wàhálà Ńlá Bẹ́ Sílẹ̀ Ní Orílẹ̀-èdè Congo, Ọ̀pọ̀ Ènìyàn Sá Àsálà Fún Ẹ̀mí Wọn

Látàrí wàhálà ńlá tí ó ń wáyé ní Orílẹ̀-èdè Congo, àwọn ará ìlú ti ń sá ní kẹ̀tí-kẹ̀tí lọ sí Burundi fún ìdáàbò bò ẹ̀mí wọn   Ní ọ̀ṣẹ̀ tí ó kọjá, ìjọba Orílẹ̀-èdè Burundi fi léde pé àwọn…

Ìròyìn Ayọ̀: Síṣí Gbọ̀ngàn Ọ́ọ́fìsì Àti Ilé Ìgbé Àjọ NDLEA Wáyé Ní Ìlú Yola

Ìjọba Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ti sí gbọ̀ngàn ọ́ọ́fìsì àti ilé ìgbé fun àjọ tí ó ń gbógun ti lílo òògùn olóró, alákọ̀ọ́kọ́ irú rẹ̀ èyí tí ó wà ní ìlú Yola, Ìpínlẹ̀ Adamawa   Gbọ̀ngàn tuntun náà,…

Àjọ FERMA Ń Se Bẹbẹ, Mínísítà Sàbẹ̀wò Sí Àtúnṣe Òpópónà Ní Ìpínlẹ̀ Nasarawa

Mínísítà kejì Fún Àkànṣe Iṣẹ́  tí ó tún jẹ́ alámójútó àjọ tí ó ń sàtúnṣe òpópónà, Bello Mohammed Goronyo ti gbóríyìn fún Ààrẹ Bọla Ahmed Tinubu fún ìpinnu rẹ̀ láti mú ìdàgbàsókè bá ìpèsè àti…
button