Take a fresh look at your lifestyle.

Ọwọ́ Sìkún Àwọn Agbófinró Tẹ Arákùnrin Kan Tí Ó Pa Òògùn Olóró Mọ́ Sínú Bàtà

Àjọ tí ó ń gbógun ti lílo òògùn olóró ní orílẹ̀ èdè wa National Drug Law Enforcement Agency, NDLEA,  ti fi ọwọ́ òfin mú agbénú òkùnkùn sebi kan, ẹni ọdún mẹ́tàdínlọ́gọ́ta (57), Lawal Lateef Oyenuga ní òpin ọ̀sẹ̀.…

Gómìnà Ìpínlẹ̀ Kaduna Gba Akẹgbẹ́ Rẹ̀ Nímọ̀ràn Láti Lo Ànfààní Ètò Ọ̀gbìn Fún…

Gómìnà ìpínlẹ̀ Kaduna ti gba àwọn akẹgbẹ́ rẹ ní ìmọ̀ràn láti lo ànfààní ètò ọ̀gbìn fún ìgbélárugẹ ọrọ̀ ajé àti mímú ọ̀tọ̀ǹkùlú ènìyàn jáde kúrò nínú ìsẹ́. Ó fi ìmọ̀ràn náà léde níbi àjọ…

Àbá láti Dá Ibùdókọ̀ ọkọ̀ Ojú Omi Sílẹ̀ Ní Ìpínlẹ̀ Ondo Ti Jẹ́ Ìtẹ́wọ́gbà Igbákejì…

Igbákejì ààre orílẹ̀ èdè Nàìjíríà ọ̀jọ̀gbọ́n Yẹmi Osibajo ti fi ọwọ́ sí àbá láti dá ibùdókọ̀ ọkọ̀ ojú omi sílẹ̀ ní ìpínlẹ̀ Ondo. Ó se àpèjúwe rẹ̀ gẹ́gẹ́ bíi ohun tí ó tọ́ láti se. Agbẹnusọ rẹ̀,…

Wíwà Ní Ipò Adarí Se Pàtàkì Fún Àwọn Obìnrin- Aya Gómìnà Ìpínlẹ̀ Niger Pàrọwà

Aya Gómìnà ìpínlẹ̀ Niger, Dókítà Amina Abubakar Sanni Bello ti fi àìdùnnú rẹ̀ hàn fún ìfàsẹ́yìn àwọn obìnrin níbi ipò adarí ní orílẹ̀ èdè Nàìjíríà.   Dókítà Amina sọ ọ̀rọ̀ náà níbi ìdánilẹ́kọ̀ọ́…
button