Nàìjíríà Yóò Gbàlejò Àwọn Ilé iṣẹ́ Ọkọ̀ Oníná Tí China
Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà tí ṣètò láti gbàlejò àwọn ilé-iṣẹ́ ọkọ̀ ayọkẹlẹ oníná bí Orílẹ̀-èdè China tí n kéde ìpinnu wọ́n.
Aṣojú Ilú China sí Nàìjíríà, Yu Dunhai, sọ èyí l'àkókò àbẹwò kán sí Mínísítà fún Àwọn òun alumọni tó lágbára tí…