Take a fresh look at your lifestyle.

Orílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà Fún Nàìjíríà Ní Ẹgbẹ̀rún Lọnà Àádọ́run Dọla ‎

Ìjọba Orílẹ̀-èdè Améríkà ló fún Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ní owó ẹbùn ẹgbẹ̀rún lọnà àádọ́run dọla ($90,000) latari àdéhùn àjọṣepọ̀ lórí ìtọ́jú Oun-ìní Àṣà tí ìnáwó Ọdún 2023, fún ìdáàbòbò àwọn òun-ìní àti òun ọ̀ṣọ́ Nok. ‎ ‎ Ẹbùn owó náà ní…

Àwọn Olùdarí Lake-Chad Ṣé Ìjíròrò Ní Maiduguri Lórí Ìdàgbàsókè Agbègbè Náà

Àpéjọ pọ̀ àwọn Gómìnà Lake Chad tí bẹ̀rẹ ìpàdé lónì ní Maiduguri, Ìpínlẹ̀ Borno, lẹ́yìn tí ìkéde tí wáyé tẹ́lẹ̀ látí ẹnu Ìjọba Ìpínlẹ̀ Yobe ní àwọn ọjọ́ díẹ̀ sẹ́yìn. ‎ ‎ Ìgbákejì Ààrẹ Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, Kashim Shettima, ní wọ́n n'ìrètí…

Nàìjíríà Ṣé Ìfilọ́lẹ̀ Ibùdó Ìtajà Fáàárí Ńlá Ni Borno L’ójúnà Látí Pèsè Iṣẹ́ ‎

Ìjọba Nàìjíríà tí ṣé ìfilọ́lẹ̀ ọjà fáàárí nlá kán ni Maiduguri, Olú-ìlú Ìpínlẹ̀ Borno, pẹ̀lú afojusun látí pèsè iṣẹ́ tó fẹ́ tó ẹgbẹ̀rún àádọ́ta nípasẹ ilé-iṣẹ́ náà. ‎ ‎ Ní ìtẹ̀síwájú àtìlẹ́yìn tí oní bílíọ̀nù márùn-dín-lọgọ́rin (N75b)…

Ní Ọjọ́ Kínní Oṣù Kẹta, Nàìjíríà Ṣèlérí Láti Mú Ìrọ̀rùn Bá Ọnà Látí Gbá Ìwé Ìrìnàjò Ní Kíkún

Ìjọba Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà tí kéde ọjọ́ kínní Oṣù kẹta ọdún yìí gẹ́gẹ́ bí ìbẹrẹ ọjọ́ tí ìwé ìrìnnà yóò dí tí orí ayélujára pátápátá l'ójúnà látí mú ìrọ̀rùn àti ààbò bá àwọn ọmọ Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà. ‎ ‎ Mínísítà fún intiriọ, Dókítà…

Ìbúgbàmù Ọkọ̀ Àjàgbé èpò: Ààrẹ Tinubu Darí Àjọ NOA Láti Bẹ̀rẹ Ìpolongo Kàn Jákèjádò Orílẹ̀-èdè

Ààrẹ Bola Ahmed Tinubu ti pàṣẹ fún àjọ tó ń ri sí ìpolongo (National Orientation Agency NOA), láti bẹ̀rẹ̀ ìpolongo ètò ẹ̀kọ́ jákèjádò orílẹ̀-èdè Nàìjíríà fún àwọn aráàlú lórí ewú tó wà nínú gbígba èpò tó dànù nígbàtí àwọn ọkọ̀ àjàgbé èpò…

Ìyàwó Ààrẹ Tí Ṣé Ìfilọ́lẹ̀ Ilé-ìwé Gíga Túntún Fún Àwọn Ọmọ Obínrin Ni Ìpínlè Osun

Ìyáàfín àkọkọ́ tí Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, Ìyáàfín Oluremi Tinubu, tí ṣí ilé-ìwé túntún fún àwọn ọmọbìnrin tó jáde kúrò ní ilé-ìwé nítorí oyún àìlérò, ìwa-ipá nínú ilé àti àwọn ìṣòro owó láti máṣe juwọ́ sílẹ̀ láti ṣaṣeyọri àwọn àlá àti…
button