Take a fresh look at your lifestyle.

Ààrẹ Tinubu Pàdà Sí Abùjá Lẹ́yìn Ìpàdé Ní Tanzania

Lekan Orenuga

142

Ààrẹ Bola Ahmed Tinubu tí pàdà sí Olú-ìlú ní Abuja lẹ́yìn ìpàdé àwọn Olórí Orílẹ-èdè ní ilẹ̀ Áfíríkà ní Dar es Salaam, Tanzania.

‎ Ní irọlẹ ọjọ́ Ìṣẹgun ní ọkọ òfurufú tí Ààrẹ balẹ̀ sí ilé-iṣẹ́ ọkọ Òfurufú tí Nnamdi Azikiwe ní Abuja ní nnkan bíi ago mẹjọ kú ogún iṣẹ́jú.

‎ Femi Gbajabiamila, olórí àwon òṣìṣẹ́ Ààrẹ, Mínísítà tí Ìpínlẹ̀ fún Ìdáàbòbò, Bello Matawalle, àti Olùdámọ̀ràn Ààrẹ lórí Ààbò Orílẹ̀-èdè, Nuhu Ribadu, atí àwọn òṣìṣẹ́ ìjọba gíga mìíràn ló tẹwọgbà Ààrẹ ní papakọ̀ Òfurufú ní Abuja

‎ Nínú Àpéjọ ọlọjọ méjì, Ààrẹ Tinubu tún ṣé ìlérí rẹ̀ láti jẹ́ kí èpò rọbi lilo dí òun ìrọ̀rùn fún àwọn olùgbé orílẹ-èdè náà.

Comments are closed.

button