Ìpànìyàn: Ààrẹ Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Kẹdun Pẹ̀lú Ìjọba Ìpínlẹ̀ Benue
Ààrẹ Muhammadu Buhari tí bú ẹnu àtẹ lù ikọlù tó ṣẹṣẹ wáyé ní ìpínlẹ̀ Benue.
Nínú ọrọ rẹ̀, Ààrẹ sọ pé kò sí itẹwọgbà fún ẹnikẹ́ni láti gbà ẹmi ẹnìkejì yálà darandaran ní tàbí àgbẹ̀.
“Ẹnikẹ́ni kò gbọ́dọ̀ kọlù ẹnikẹ́jì nítorí ọ̀nà…