Ààrẹ Bola Tinubu tí kúrò ní Olú-ìlú orílẹ̀-èdè ní Abuja, látí lọ́ síbí ìparí ayẹyẹ nlá kàn tí wọ́n ṣètò látí ṣé ìsàmì sí ayẹyẹ ọgọ́ta (60) ọdún tí ìdásílẹ̀ Ilé-ẹ̀kọ́ gíga tí Ààbò Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ní Kaduna.
Ní ọjọ́ karún Osù Kéjì, Ilé-ẹ̀kọ́ gíga náà ṣé àfihàn ààmì kàn àtí itẹwọgbà tí n ṣé tí ayẹyẹ ọgọ́ta ọdún náà gẹ́gẹ́ bí iṣẹ́ ìsàmì sí rẹ̀, èyítí o bẹ̀rẹ̀ ní ọjọ́ mẹ́ta sẹ́yìn ní gbọ̀ngán NDA kàn ní Afaka.
NEWS FLASH:
President Bola Ahmed Tinubu @officialABAT leaves Abuja to participate in the Nigerian Defence Academy's Diamond Jubilee celebration in Kaduna. #NDA #DiamondJubilee #Kaduna pic.twitter.com/BhAbc2PBLi
— Voice of Nigeria (@voiceofnigeria) February 10, 2024
HAPPENING NOW #NDAat60
NIGERIAN DEFENCE ACADEMY 60TH ANNIVERSARY TROOPING AND PRESENTATION OF COLOUR PARADE
LIVE on NTA.
LIVESTREAM: https://t.co/tlyp50IWDb pic.twitter.com/yGytfUyxy9
— Nigerian Army (@HQNigerianArmy) February 10, 2024
Ààrẹ Tinubu ní a ní ìrètí pé yóò pàdà sí Abuja lọ́jọ́ Àbámẹ́ta, ọjọ́ kàn náà.