Adarí Ilé Ìgbìmọ̀ Asòfin Ìlú Abuja, Fẹmi Gbajabiamila ti dìbò ní ibùdó ìdìbò Ilé-ìwé alákọ̀bẹ́rẹ̀ẹ̀ Elizabeth Fowler, Masha- Suurulere.
Ó sọrọ ní déédé agogo mọ́kànlá òwúrọ̀ ọjọ́ Àbámẹ́ta nígbà tí ó dìbò tán. Ó sàlàyé pé ètò náà lọ ní ìrọwọ́-rọsẹ̀.
Gbajabiamila wá fi àfojúsùn rẹ̀ hàn pé, ètò náà yóò kẹ́sẹ járí jákè-jádò Orílẹ̀ Èdè Nàìjíríà.
Leave a Reply