Take a fresh look at your lifestyle.

Ìbásepọ̀ Tí Ó Múná Dóko Yóò Wáyé Láàrin Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Àti Brazil

154

Ààrẹ Bọla Ahmed Tinubu sọ pé Nàìjíríà ti gbáradì láti ta kókó ìbásepọ̀ rẹ̀ pẹ̀lú Orílẹ̀-èdè Brazil

 

Ààrẹ sọ ọ̀rọ̀ náà nígbà tí ó pàdé Ààrẹ Luiz Inacio Lula da Silva ti Orílẹ̀-èdè Brazil, ní ìlú Addis Ababa, Orílẹ̀-èdè Ethiopia, ní ọjọ́ Ajé

 

Ó sàpèjúwe ìbásepọ̀ náà gẹ́gẹ́ bí èyí tí yóò mú ànfààní bá ọrọ̀ ajé Orílẹ̀-èdè méjéèjì náà

 

Comments are closed.

button