Gbajúgbajà òṣèré tí gbogbo ènìyàn mọ̀ nípasẹ̀ eré ẹbí olókìkí ‘The Johnsons’ ti di olóògbé ní ọjọ́ Àìkú,ọjọ́ kẹtàdín-lógún, Oṣù Keje, ọdún 2022 ní ilé-ìwòsàn kan ní ìpínlẹ̀ Delta.
Ada Ameh, ẹni ọdun mejidin-laadọta, jẹ oṣere Naijiria ti o ti lo ju ogun ọdun lọ ni ile-iṣẹ fiimu Naijiria ati pe ti a mọ pupọ julọ fun ipa to ko bi Anita ninu fiimu ọdun1996 ti akole rẹ jẹ “Domitilla” ati bi Emu Johnson ninu ere ori tẹlifisiọnu ti o gba ami-eye ni Naijiria ti akole rẹ n jẹ ‘The Johnsons’.
Agba oṣere Nollywood naa ni ọmọbinrin kan ti o ku ni Oṣu Kẹwa, ọdun 2020.
Leave a Reply