Àwọn ènìyàn ààdọ́fà míràn tún ti kó ààrùn covid ní orílẹ̀-èdè.
Ile-iṣẹ to n mojuto ajakalẹ aarun lorile-ede NCDC sọ eleyi di mimọ lori wẹẹbu wọn.
Gẹgẹ bii ile-iṣẹ ọhun,NCDC sọ pe awọn eniyan aadọfa ọhun jẹyọ lati ipinlẹ mejila- Lagos (mẹtedin-lọgbọn), Katsina (mẹtale-logun), Rivers (ogun), Ondo (mọkanla), Kaduna (mẹsan), Olu-ilu (mẹfa), Oyo (mẹfa), Plateau (mẹta), Osun (meji), Ekiti (ẹyọkan), Gombe (ẹyọkan), Zamfara (ẹyọkan).
Lọwọlọwọ bayii,eniyan ẹgbàájì le ni ọ̀kẹ́ mẹ̀wá abo o le ni èjì le ni àádọ́rùn lo ti ko aarun corona, ẹ̀ẹ́dẹ́gbàrin- le- ni- ọ̀kẹ́- mẹ̀wá- o- le –ni- eérinlá- le- ni- ojì-le-nigba eniyan ti gba iwosan,ti eniyan ẹ̀rin-le-ni-okòó- din- lẹgbẹ́ẹ́ẹdógún si ti jẹpe oluwa.
Leave a Reply