Take a fresh look at your lifestyle.

Ìdàgbàsókè Àti Ìkópa Àwọn Ọ̀dọ́ Nínú Ìsèjọba Jẹ Ìjọba Lógún- Ayọdele Ọlawande

Ìjọba Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ti sàfihàn ìfarajì rẹ̀ fún ìdàgbàsókè àti ìkópa àwọn ọ̀dọ́ nínú ètò ìsèjọba, ìdàgbàsókè ìgbèríko gẹ́gẹ́ bí àwọn ìgbésẹ̀ tí yóò jẹ́ kí àlàáfíà jọba ní Orílẹ̀-èdè…

Àyájọ́ Òsìṣẹ́: Adarí Ilé Asòfin Jẹ́jẹ̀ẹ́ Ìbásepọ̀ Tí Ó Gún Régé Pẹ̀lú Àjọ Òsìṣẹ́

Adarí Ilé Ìgbìmọ̀ Asòfin, Godswill Akpabio ti jẹ́jẹ̀ẹ́ pé ilé ìgbìmọ̀ Asòfin ẹlẹ́kẹ̀ẹwàá lábẹ́ ìsàkóso òun yóò ní ìbásepọ̀ tí ó dán mọ́rán gẹ́gẹ́ bí ó se sọ lásìkò àyájọ́ òsìṣẹ́ Ó gbósùbà…

Àyájọ́ Àwọn Òsìṣẹ́ : Olórí Àwọn Òsìṣẹ́ Ìjọba Dáwọ̀ọ́ Ìdùnnú Pẹ̀lú Wọn

Olórí àwọn Òsìṣẹ́ Ní Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, Arábìnrin Didi Esther Waison-Jack ti fi ìdùnnú ọkàn rẹ̀ hàn sí àwọn òsìṣẹ́ ní Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, papàá jùlọ àwọn tí ó farajì,  tí wọn kò sì kùnà…

Ikú Ni Èrè Ẹ̀sẹ̀ : Ọmọ Ogun Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Kan Jẹ̀bi Ẹ̀sùn Ikú Pẹ̀lú Yíyẹgi Fun-…

Ilé Ìdájọ́ Àjọ Ọmọ Ogun tí ó wà ní Ọ́ọ́fìsì Àpapọ̀ Àjọ náà ní Ìlú Enugu ni ó ti dájọ́ ikú fún Ọmọ Ogun Adamu Muhammed léyìí tí wọn yóò yẹgi fún-un títí ẹ̀mí yóò fi bọ́ ní ọrùn rẹ̀ àti ojúgbà rẹ̀…

Ẹ Jẹ́ Kí Ìsọ̀kan Àti Ìdàgbàsókè Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Jẹ Yín Lógún – Ààrẹ Tinubu…

Ààrẹ Bọla Ahmed Tinubu ti pàrọwà sí ọmọ Nàìjíríà láti wà ní ìsọ̀kan kí wọ́n sì rí i dájú pé Orílẹ̀-èdè jẹ wọ́n lógún nítorí pé ìtẹ̀síwájú Nàìjíríà se pàtàkì ju ohun kóhun lọ   Ààrẹ sọ ọ̀rọ̀…
button