Ìdàgbàsókè Àti Ìkópa Àwọn Ọ̀dọ́ Nínú Ìsèjọba Jẹ Ìjọba Lógún- Ayọdele Ọlawande
Ìjọba Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ti sàfihàn ìfarajì rẹ̀ fún ìdàgbàsókè àti ìkópa àwọn ọ̀dọ́ nínú ètò ìsèjọba, ìdàgbàsókè ìgbèríko gẹ́gẹ́ bí àwọn ìgbésẹ̀ tí yóò jẹ́ kí àlàáfíà jọba ní Orílẹ̀-èdè…