Take a fresh look at your lifestyle.

Ilé Asòfin Se Àtìlẹyìn Fún Ìgbésẹ̀ Ààrẹ Látàrí Ìkéde Ìjọba Pàjáwìrì Ní…

Ilé ìgbìmọ̀ Asòfin kejì ti buwọ́lu ìgbésẹ̀ Ààrẹ Bọla Ahmed Tinubu pẹ̀lú ìkéde ìjọba pàjáwìrì tí ó wáyé ní ìpínlẹ̀ Rivers   Wọ́n se àtìlẹyìn fún ìgbésẹ̀ náà lẹ́yìn ìgbà tí wọ́n gba ìwé àtẹ̀jísẹ́…

Ọ̀pọ̀ Ènìyàn Pàdánù Ẹ̀mí Níbi Ìsẹ̀lẹ̀ Ọ̀kọ̀ Epo Tí Ó Bú Gbàmù Ní Ìlú Abuja

Ìsẹ̀lẹ̀ ìjàm̀bá ọkọ̀ epo wáyé ní ìlú Abuja léyìí tí ọkọ̀ náà gbiná ní orí afárá karu, ní àgbègbè Nyanya ní òpópónà Abuja sí Keffi, èyí tí ó mú kí iná wáyé tí ó sì jó ọkọ̀ tí kò dín ní ọgbọ̀n,…

Ẹ Jìnà Sí Ẹlẹ́yàmẹ̀yà Kí Ìsọ̀kan Orílẹ̀-èdè Le è Tẹ̀síwájú- Igbákejì Ààrẹ Pàrọwà…

Igbákejì Ààrẹ Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, Kashim Shettima ti pàrọwà sí adarí ilé ìgbìmọ̀ asòfin àpapọ̀ láti tẹ̀síwájú nínú ojúse wọn, èyí tí yóò mú kí ìsọ̀kan, ìdàgbàsókè wáyé, kí wọ́n sì jìnà sí…

Ẹgbẹ́ APC Bu Ẹnu Àtẹ́ Lu El-Rufai Látàrí Sísọ Ọ̀rọ̀ Òdì Sí Ìgbésẹ̀ Ìjọ̀ba

Ẹgbẹ́ òsèlú APC ti sàpèjúwe ọ̀rọ̀ òdì tí gómìnà Ìpínlẹ̀ Kaduna tẹ́lẹ̀rí sọ sí ẹgbẹ́ náà nígbà tí ó sọ wípé ẹgbẹ́ náà ti yapa sí òfin àti àlàkalẹ̀, gẹ́gẹ́ bi irọ́ pátápátá, ọ̀rọ̀ tí kò rẹ́sẹ̀ walẹ̀…

Mínísítà Fún Àkànse Isẹ́ Ń Se Takun-Takun – Alẹ́nulọ́rọ̀ Ẹgbẹ́ Òsèlú LP Juwọ́ Káre

Alẹ́nulọ́rọ̀ kan nínú ẹgbẹ́ òsèlú LP ẹka ìpínlẹ̀ Ebonyi, Ọ̀mọ̀wé Emmanuel Ezeh ti sàpèjúwe gómìnà Ìpínlẹ̀ Ebonyi tẹ́lẹ̀rí tí ó tún jẹ́ mínísítà fún àkànṣé iṣẹ́, Onímọ̀-ẹ̀rọ David Umahi gẹ́gẹ́ bí mínísítà…
button