Take a fresh look at your lifestyle.

Ẹgbẹ̀rún Márùn Ó Lé Díẹ Ọmọ Ẹgbẹ́ Òṣèlú APC Darapọ̀ Mọ́ Ẹgbẹ́ Òṣèlú PDP Ní Ìpínlẹ̀ Kogi

Ó lé ní Ẹgbẹ̀rún márùn Ọmọ Ẹgbẹ́ Òṣèlú APC tí wọn lọ darapọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ oṣèlú alátakò PDP ní Ìpínlè Kogi báyìí. Àwọn ọmọ ẹgbẹ́ òṣèlú APC ní ọjó Àìkú ní Avrugo àti wọ́ọ̀dù tó múlé tìwọn, ní agbègbè ìbílẹ̀ ìjọba Igalamela/Odolu ti ìpínlẹ…

Àjọ Tó Ń Sọ Nípa Bójú Ọjó Se Rí Ti Rọ Àwọn Àgbẹ̀ Orílè-èdè Yìí Láti Ka Ìwòye Ọ̀rọ̀ Ojú Ọjọ́ Sí

Àjọ to ń sọ nípa bóju Ọjó se rí (NiMET) ti Orílè-èdè yìí ti sọ pé bí àwọn àgbẹ̀ ṣe ń pàdánù ọ̀pọ̀ irè oko lórílẹ̀ èdè yìí kò sẹ̀yìn àìka ọ̀rọ̀ àjọ náà tó sọ̀rọ̀ nípa bójú ọjó se rí sí. Adarí ẹ̀ka ti ojú ọjọ́ NiMET , Ògbẹ́ni Adélékè…

2023: Èmi Kò Tíì Yọwọ́ Kúrò Nínú Ìdíje Sípò Ààrẹ – Tinúbú

Olùdíje fún ipò ààrẹ lábẹ́ àsíá ẹgbẹ́ òṣèlú APC, Asíwájú Bọ́lá Ahmed Tinúbú pariwo síta tantan pé òun kò tíì yọwọ́ Kúrò nínú ìdíje sípò ààrẹ. Tinúbú, ẹni tó fi fídíò kan síta níbi to ti ń wa kẹ̀kẹ́ eré ìdárayá rẹ̀ nírọ̀lẹ́ ọjọ́ Àìkú láti…

Oríire Gómìnà Umahi: Ẹgbẹ Òṣèlú Ìpínlẹ̀ Ebonyi  Gbósùbà Fún Ilé Ẹjọ́

Ní ọjọ ọjó ẹtì, Alága ẹgbẹ́ òṣèlú APC ti Ìpínlè Ebonyi, Stanley Emegha gbé òsùbà ràbàndẹ̀ fún ìdájọ tí ilé ẹjọ tó kalẹ̀ sí ìlú Abuja fún ìdájọ́ rere ìbò kòmẹsẹ̀ ó yọ ti ẹgbẹ́ òṣèlú APC tó gbé Gómìnà David Umahi wọlé bí Olùdíje òtítọ́ ti…
button