Nàìjíríà Kẹdun Pẹ̀lú Orílẹ̀-èdè South Korea Lórí Àjálù Tó Ṣẹlẹ̀ Sí Wọ́n
Ààrẹ Muhammadu Buhari tí kẹdun ọkàn sí Ààrẹ Yoon Suk-yeo, Ìjọ̀ba àti àwọn ènìyàn Orílẹ̀-èdè South Korea, àti sí àwọn ìdílé tí àwọn ọmọ wọ́n pàdánù ẹmi nínú ìṣẹlẹ̀ àjálù tó wáyé ní Itaewon, ni àgbègbè Seoul.
Ààrẹ wà fí ádùrá ìwòsàn ní…