Ààrẹ Ilé-ìgbìmọ̀ Aṣòfin Àgbà Ṣé Ayẹyẹ Àwọn Ògo-wẹ̀rẹ̀ Naijiria
Ààrẹ ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, Ahmad Lawan ti kí àwọn ọmọdé orílẹ̀-èdè Nàìjíríà fún ayẹyẹ ọjọ́ àwọn ọmọdé ti ọdún yìí.
Lawan ṣé àkíyèsí pé àwọn ọmọdé jẹ́ apakan pàtàkì tí àwùjọ tó yẹ́ àkíyèsí pàtàkì, Ààbò àti ìtọjú.…