Take a fresh look at your lifestyle.

Ààrẹ tẹ́lẹ̀ rí Jonathan kí àwọn ọmọ lẹ́yìn Kírísítì kú ọdún Kérésìmesì

Ààrẹ tẹ́lẹ̀ rí Goodluck Ebele Jonathan ti kí gbogbo ọmọ Nàìjíríà kú ọdún Kérésìmesì, tí ó sì ń rọ̀ wọ́n láti ní ìfẹ́, àlààfíà, ìrẹ̀lẹ̀ ọkàn, àti ìfìgbádùn ara ẹni sílẹ̀ fún nǹkan mìíràn. Ninu…

Ológun Nàìjíríà: Mínísítà kí àwọn ọmọ Ológun tí wọ́n ṣẹ̀ṣẹ̀ gba ìgbéga kú oríire

Mínísítà ìpínlẹ̀ fún ètò ààbò, Dókítà Muhammed Bello Matawalle, ti kí àwọn ọmọ Ológun tí wọ́n ṣẹ̀ṣẹ̀ gba ìgbéga lẹnu iṣẹ́ jákèjádò Nàìjíríà : ológun Nàijíríà, ológun òfurufú, àti ológun oju omi ku…

Ẹjẹ́ ka ní ìṣọ̀kan láti kojú àwọn ọ̀tá wa – Ọ̀gá àgbà fún àwọn òṣìṣẹ́ elétò ààbò

Bí àwọn ọmọ Nàìjíríà ṣe darapọ̀ mọ́ àgbáyé láti ṣàjọyọ̀ ọdún Kérésìmesì àti ọdún tuntun,  Ọ̀gá àgbà fún àwọn òṣìṣẹ́ elétò ààbò ní Nàìjíríà, Ajagun Christopher Musa, rọ àwọn ọmọ Nàìjíríà láti ní…

Kérésìmesì: Ààrẹ Tinubu ṣàjọyọ̀ pẹ̀lú àwọn ọmọ lẹ́yìn kírísítì

Ààrẹ Bọla Ahmed Tinubu ti kí àwọn Kírísítíẹ́nì kú oríire bí wọ́n ṣe ń ṣàjọyọ̀ ọdún Kérésìmesì, tí ó sì sọ pé ìjọba òun yóò túnbọ̀ máa ṣe ìmúṣẹ ètò ìtura láti mú ìdẹ̀rùn bá àwọn tó ní ìpalára…

Ìwúyè: Igbákejì adarí ilé-ìgbìmọ̀ kí ààrẹ Tinubu àti igbákejì rẹ̀ kú oríire

Igbákejì adarí ilé-ìgbìmọ̀ Aṣojú, Benjamin Kalu ti kí ààrẹ Tinubu Bọla Tinubu àti igbákejì rẹ̀, Sẹ́nétọ̀ Kashim Shettima kú oríire fún ìfijoyè ní ilẹ̀ Igbo. Wọn fi oye ọtọọtọ da awọn adari mejeeji lọla nigba ti wọn wa…
button