Mínísítà fún ọ̀rọ̀ inú ìlú, Àwọn tó kù lọ fún ìbánisọ̀rọ̀ ààrẹ ní gbogbo ìgbà ní…
Mínísítà fún ọ̀rọ̀ inú ìlú Olubunmi Tunji-Ojo, pẹ̀lú àwọn mínísítà mẹ́ta mìíràn, wà ní ìjókòí ní gbọ̀ngàn ààrẹ ní Villa , ní ọjọ́ Ìṣégun fún ìbánisọ̀rọ̀ ààrẹ Bọla Ahmed Tinubu tí máa á wáyé ní…