Take a fresh look at your lifestyle.

Ìjọba ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun buwọ́lu gbígba ẹgbàárún olùkọ́ni síṣẹ́

Ìjọba ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun iwọ̀ oòrùn Nàìjíríà ti buwọ́lu gbígba ẹgbàárún olùkọ́ni àti àwọn òṣìṣẹ́ ilé ìwé ọ̀tà-dín-lẹ́ẹ́wá-lé-nígba sí ṣẹ́. Gẹgẹ bi iroyin ti wọn fi sita ti Olawale Rasheed, ti agbẹnusọ fun gomina…

AFCON: Adarí ilé ìgbìmọ̀ nígbà kan rí gbóríyìn fún àṣeyege ìpele ìkẹyìn Super Eagles

Adarí ilé ìgbìmọ̀ Aṣòfin Nàìjí́ríà nígbà kan rí, Sẹnetọ Ahmad Lawan, ti kí Super Eagles kú oríire fún fífàgbà han Bafana Bafana ti South Africa níbi ìpele àti bọ́ sí ìkẹyìn ìfigagbága ife orílẹ̀-èdè Adúláwọ̀…

Ètò ìjọba: Aṣòfin rọ àwọn ọmọ Nàìjíríà kí wọn ó ní sùúrù

Wọ́n ti rọ àwọn ọmọ Nàìjíríà láti ní sùúrù kí wọ́n ó sì fi ààyè gba àwọn etò tí ààrẹ B̀ọla Ahmed Tinubu fi lọ́lẹ̀ fún àǹfààní ara wọn. Aṣiwaju awọn ọmọ Yoruba ni Kano, Ọgbẹni  Leke Abejide ti o ṣoju agbegbe…

Gbajabiamila gbóríyìn fún ètò ìdìbò, pè fún ìrànlọ́wọ́ láti fòpin sí adigunjalè

Ọ̀gá àgbà fuń àwọn òṣìṣẹ́ ààrẹ Tinubu, Ọ̀gbẹ́ni Fẹmi Gbajabiamila ti gbóríyìn fún ìgbìmọ̀ olómìnira tí ń mójútó ètò ìdìbò lórílẹ̀-èdè, INEC fún bí ó ṣe ṣètò àdìkù ìbò nírọ̀wọ́ rọsẹ̀ ní Surulere…
button