Take a fresh look at your lifestyle.

AnambraDecides:Ètò ìdìbò gómìnà ìpínlẹ̀ Anambra forí ṣánpọ́n

Àjọ elétò ìdìbò olómìnira orílẹ̀-èdè (INEC) ti kéde  ìdìbò gómìnà ìpínlẹ̀ Anambra ti ọdún 2021 pé ó forí ṣánpọ́n  nítorí pé  ìdìbò kò wáyé ní ìjọba ìbílẹ̀ Ihiala ní ìpínlẹ̀ náà. Oṣiṣẹ ajọ ọhun…

Anambra: Ẹgbẹ́ bẹnu àté lu bíí Àwọn abarapáá kò ṣe láǹfààní láti dìbò

Ẹgbẹ́ àwọn olùwòye ìdìbò ti bẹnu àtẹ́ lu bí  ìdá mẹ́rìnlé-láàdọ́ta nínú àwọn ọ̀nà tí ó lọ sí àwọn ààyè ìdìbò tí wọ́n ṣe àyẹ̀wò rẹ̀  fún Àwọn abara páá (PWDs) lákòókò ìdìbò gómìnà ní ọjọ…

Ìjọba Àpapọ̀ Tún Ti Sún Gbèdéke Ìforúkọsílẹ̀ NIN àti SIM Síwájú

Ìjọba àpapọ̀ ti sún  gbèdéke fún  ìforúkọsílẹ̀  NIN àti SIM síwájú. Èyí tí ó yẹ kí ó wá sí òpin ní ìparí oṣùn kẹẁáa; sùgbọ́n  ìgbìyànjú láti ríi pé gbogbo ènìyàn ní àǹfààní láti kópa nínú…

Orílẹ̀-èd̀e South Africa yóò Rán ẹgbẹ̀rún mẹ́wàá ọmọ ogun lọ sí ìdìbò Agbègbè

South Africa yóò rán ẹgbẹ̀rún  mẹ́wàá ọmọ-ogun  láti lọ ṣètò ààbò lákòókò àwọn ìdìbò yàn tó ń bọ̀, tí yóò bẹ̀rẹ̀ ní ọ̀sẹ̀ tó ń bọ̀. Ile igbimọ aṣofin South Africa ni Ọjọ ru ṣọ  pe, aarẹ Cyril Ramaphosa ti…

Iṣé Ojú-ọjọ́: Wọ́n ti rọ Àwọn adarí Àgbáyé láti mú ìlérí ọdún 2009 ṣẹ

Ìjọba orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ti képè àwọn adarí àgbáyé láti mú ìléríi  àti ṣàkójọ iyẹ owó tó tó ọgọ́rùn ún bílíọ́nù dọ́là fún ọdún kan ní ọdún 2020 wá sí ìmúṣẹ láti ṣe àtìlẹ́yìn iṣẹ́ ojú-ọjọ́ ní…

Nàìjíríà, Kòríà yóò bẹ̀rẹ̀ ìpele Kejì Ìjọba nípa lílo ìmọ̀ ẹ̀rọ

Lẹ́hìn  tí ìpele àkọ́kọ́  iṣẹ́ àkànṣe ìjọba lílo ìmọ̀ ẹ̀rọ ti jẹ́ àṣeyọrí, Ìjọba orílẹ̀-èdè Nàìjíríà àti  Kòríà ti ṣètò láti bẹ̀rẹ̀ ìpele kejì  iṣẹ́ àkànṣe ní Nàìjíríà. Minisita fun Ibaraẹnisọrọ ati…

Ààrẹ Bùhárí yóò ṣèfilọ́lẹ̀ ìpàdé àpérò fún ìdáábòbò ètò ẹ̀kọ́

Ààrẹ orílẹ̀ -èdè Nàìjíríà, Mùhámmádù Bùhárí yóò ṣe ìfilọ́lẹ̀ ìpàdé àpérò káríayé ìpele kẹrin, fún ìdáábòbò ètò ẹ̀kọ́ ní ọjọ́ ìṣẹ́gun, ní ọ̀sẹ̀ tí ó ń bọ̀. Eleyi jẹyọ ninu  alaye kan ti  Oludari…
button