Take a fresh look at your lifestyle.

Kòsí aáwọ̀ kankan láàrin àwọn aláṣẹ àti aṣòfin – ilé-iṣẹ́ ààrẹ

Ilé-iṣẹ́ ààrẹ ti sojú abẹ níkòó lórí àríyànjiyàn tí ó wáyé láàrin Aláṣẹ àti àwọn abala aṣòfin  ìjọba lórí àwọn àtúnṣe inú ìsúná ọdún 2022. Agbẹnusọ fun Aarẹ, Garba Shehu, ninu ọrọ kan, sọ pe awuyewuye…

Ìdìbò Gómìnà Èkìtì: Olùdámọ́ràn Pàtàkì kìlọ̀ láti Lòdì sí ìwà ẹlẹ́yàmẹ̀yà

Olùdámọ̀ràn pàtàkì lórí ọ̀rọ̀ òsèlú fún Ààre, Alàgbà Babáfẹ́mi Òjùdù, kìlọ̀ wípé ìyapa àti àìjọṣepọ̀ tó wà láàrin àwọn ọmọ ẹgbẹ́ òsèlú All Progressives Congress (APC) ní ìpínlẹ̀ Ekiti le mú ṣèdíwọ́…

Ọmọ ilé ìgbìmọ̀ Aṣòfin ti rọ Àwọn oníròyìn láti ṣe Iṣẹ́ wọn pẹ̀lú ọgbọ́n

Sẹ́nétọ̀ tí ń ṣojú ẹkùn Ariwá Ebonyi, Alagba Michael Ama Nnachi ti rọ àwọn akọ̀ròyìn láti tẹ̀le ìwà tí ó ń tọsẹ̀ Ìròyìn. Sẹnetọ Nnachi pe ipe yii nigba ti awọn ọmọ ẹgbẹ  Correspondents Chapel ti ajọ awọn akọroyin…

Fífa ọwọ́ àdéhùn òfin ìdìbò sẹ́yìn fún dáadáa Nàìjíríà ni – Ààrẹ

Ilé-ìgbìmọ̀ ààrẹ sọ pé  ààrẹ Mùhámmádù Bùhárí  fawọ́ ìfẹsẹ̀múlẹ̀ Àtúnse ètò Ìdìbò, (Act) 2021 sẹ́yìn fún dáadáa orílẹ̀ -èdè ni. Ninu ifiranṣẹ kan, Oluranlọwọ pataki si Aarẹ lori iroyin ati ipolongo, Farba…

NIDOE yóò Dá ibùjókòó ìdókòwò fún àwọn ọmọ Nàìjíríà tí wọ́n ń gbé ní òkè…

Ẹgbẹ́ Àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà  tó ń gbé lókè  òkun (NIDOE),  ẹ̀ka orílẹ̀-èdè Itali , sọ pé ó ń gbèrò láti kọ́ ọ̀pọ̀lọpọ̀ mílíónù dọ́là 'Diaspora Village' ní Nàìjíríà gẹ́gẹ́ ,bí ara àwọn…

Ìjàǹbá Iná Àbújá: Mínísítà fún ọmọnìyàn kẹ́dùn pẹ̀lú àwọn olùfaragbá

Mínísítà fún ètò ọmọnìyàn, ètò  àjálù àti ìdàgbàsókè àwùjọ, Sadiya Umar Farouq ti kẹ́dùn lórí ìpàdánù ọjà àti dúkìá tí ó tó bílíọ̀nù owó dọ́là Náírà, nínú ìṣẹ̀lẹ̀ iná tó wáyé ní ilé…
button