Adarí Nàìjíríà ṣàtẹ́wọ́gbà àdéhùn ikọ̀ ọlọ́kanọ̀jọ̀kan pẹ̀lú Qatar
Ààrẹ Nàìjíríà, Bọla Ahmed Tinubu ti fi dá ìjọba Qatari lójú pé òun ti ṣetán láti ṣàtẹ́wọ́gbà àwọn ìdókòwò sí orílẹ̀-èdè, ó ní òun mọ ìpeniníjà tí orílẹ̀-èdè ń kojú lọ́wọ́ ṣùgbọ́n pé ìjọba òun ń ṣe…