Take a fresh look at your lifestyle.

Gómìnà Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ Tẹ́lẹ̀ rí, Ọmọlolu Olunlọyọ Jáde Láyé

Gómìnà Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́, Seyi Makinde ti fi ikú ẹni tó ti fi ìgbà kan rí jẹ́ Gómìnà Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́, Ọ̀mọ̀wé Victor Ọmọlolu Olunlọyọ wé àdánù nlá Makinde lo sọ ọ̀rọ̀ yìí nínù àtẹ̀jáde kan eléyìí to fi kẹ́dùn pẹ̀lú ìdílé Olunlọyọ, gbogbo ọmọ…

Makinde Ni Okòwò Ti Fẹṣẹ Múlẹ̀ Ni Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ Bí Ladoja, Igbákejì Gómìnà Àti Àwọn Aṣòfin Kan Ṣe…

Gómìnà Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́, Seyi Makinde ti sọ di mímọ̀ pé ìṣèjọba òun ti dé ìpele eléyìí to fihàn pé okòwò ti rẹ́sẹ̀ walẹ̀ pẹ̀lú sisan owó tí kò dín ní Bílíọ̀nù Mẹrinlelogun (N24b) gẹ́gẹ́ bíi owó oṣù òṣìṣẹ́ ni Ìpínlẹ̀ àti Ìjọba Ìbílẹ̀. Bákan…

Ìjọba Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ ti gúnlè ṣíṣe àmúlò anfààní ìmọ̀ ẹ̀rọ aláìlééfín láti ṣe ogbin Tòmátò lọ́pọ̀ yanturu pẹ̀lú Orílẹ̀ Èdè Netherlands. Ẹni tíì ṣe Alákòóso àgbà ilé Àjọ Ìdàgbàsókè Òkòwò Iṣẹ́ Àgbẹ̀ ni Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ (Oyo State Agribusiness…

Makinde Dunnú Fún Ìyànsípò Adeladan Gẹ́gẹ́ Bíi Akọ̀wé Àgbà Ilé Iṣẹ Ìjọba Àpapọ̀

Gómìnà Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́, Seyi Makinde ti fi ìdùnnú rẹ hàn sí ìyànsípò Alhaji Rafiu Adeladan sí ipò akọwe àgbà ilé iṣẹ́ Ìjọba Àpapọ̀ Orilẹ Èdè Nàìjíríà. Ìyànsípò náà ní Ààrẹ Bola Ahmed Tinubu fi ọwọ́ sí nínú ọsẹ yìí gẹ́gẹ́ bí àtẹ̀jáde ti…

Ìjọba Àpapọ̀ Pẹ̀lú Àjọṣepọ̀ Banki Àgbáyé Ṣe Ìdánilẹ́kọ̀ọ́ Fún Ọ̀ọ́dúnrún Olùkọ́ Ilé Ẹ̀kọ́ Ìmọ̀ Iṣẹ́…

Kò dín ní Ọ̀ọ̀dúnrún (300) olùkọ́ ilé ẹ̀kọ́ ìmọ̀ ìkọ́ṣẹ́ ọwọ́ ni Ẹkùn Gúsù Ìwọ̀ Oòrùn Orílẹ̀ Èdè Nàìjíríà tó ṣe alabapin nínú Ìdánilẹ́kọ̀ọ́ ọlọsẹ̀ mẹta ti ilé iṣẹ Ìjọba Àpapọ̀ to n rí sì ètò ẹ̀kọ́ se agbatẹru rẹ̀ pẹ̀lú ibaṣepọ Bánkì Àgbáyé.…

Òṣìṣẹ́-fẹ̀yìntì Ní Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ Lù Gómìnà Seyi Makinde Lọ́gọ Ẹnu

Òṣìṣẹ́-fẹ̀yìntì ni Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ ti lu Gómìnà Seyi Makinde lọ́gọ ẹnu nígbà tí wọn fi ìdùnnú wọn hàn sí owó ìfẹ̀yìntì tó n jẹ sísan lásìkò. Àwọn Òṣìṣẹ́-fẹ̀yìntì jákèjádò Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ náà lo ko ara wọn jọ sí Ofiisi Gómìnà to kalẹ Si…
button