Take a fresh look at your lifestyle.

Ààrẹ Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Ṣé Ìpàdé Pẹ̀lú Àwọn Aṣáájú Ilé Ìgbìmọ̀ Aṣòfin Àpapọ̀ Orílẹ̀-èdè

Ọlálékan Ọ̀rẹ́núgà

0 524

Ààrẹ Bola Tinubu tí ń ṣé ìpàdé pẹ̀lú àwọn olórí ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin àpapọ̀ ní Abuja.

Àwọn tó wà níbí ìpàdé náà ní Ààrẹ Ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin àgbà, Ahmed Lawan, agbẹnusọ ilé ìgbìmọ̀ asojú-ṣófin, Femi Gbajabiamila àtí àwọn olórí ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin mìíràn.

Voice of Nigeria jábọ pé ìdí ìpàdé náà kó tíì yé ẹnikan ṣùgbọ́n ó ṣeéṣe; kó ní í ṣe pẹ̀lú ọ̀rọ̀ àwọn aṣáájú ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin kẹwàá (10th Assembly), tí yóò wáyé láìpẹ́ nínú oṣù yìí.

Tún kà nípa:Ààrẹ Tinubu Ń Ṣé Ìpàdé Pẹ̀lú Àwon Olórí Ààbò

Ní wákàtí díẹ̀ sẹyìn ní Ààrẹ ṣépàdé pẹ̀lú àwọn Olùdarí ààbò, tí wọ́n sọ fún ùn nípa ipò ààbò Orílẹ̀-èdè náà.

Ẹkùn rẹ̀rẹ̀ ìròyìn náà ń bọ̀ láìpẹ́…! Ẹ kú ojú lọ́nà..!!

Leave a Reply

Your email address will not be published. Required fields are marked *

button