Ààrẹ Muhammadu Buhari tí gbé àwọn àbá-òfin mẹ́ta lọ́ sí Ilé-ìgbìmọ̀ Aṣojú-ṣòfin fún àyẹwò.
Èyí ló farahàn nínú lẹta kàn tó kọ sí Agbẹnusọ Hon. Femi Gbajabiamila, èyítí o ká ní àpéjọ wọ́n ní ọjọ́ Ajé.
Àwọn àbá-dòfin náà ní: igbero ètò ìṣúná 2023 tí Olú-ìlú orílẹ-èdè yìí FCT, igbero ètò ìṣúná 2023 tí ìdàgbàsókè Niger/Delta (NDDC), Code of Conduct Bureau (CCB), ìwé òfin Tribunal 2022 àtí àtúnṣe ìwé òfin orílẹ̀-èdè Nàìjíríà 2022.
Agbẹnusọ ọ̀ún ká lẹta náà sí etí àwọn akẹgbẹ rẹ̀, o sí fí wọ́n lé àwọn élétó wọ́n gbogbo lọ́wọ́ fún àgbéyẹ̀wò.
Lekan Orenuga
Leave a Reply